Publicidade

Êxodo 15

Orin Mose àti Miriamu

1 15.1: If 15.3. Nígbà náà ni Mose àti àwọn ọmọ Israẹli kọ orin yìí Olúwa,

Èmi yóò kọrin Olúwa,

nítorí òun pọ̀ ògo.

Ẹṣin àti ẹni ó gùn ún

ni ó ti sọ sínú Òkun.

2 15.2: Sm 118.14; Isa 12.2. Olúwa ni agbára àti orin mi;

òun ti di Olùgbàlà mi,

òun ni Ọlọ́run mi, èmi ó yìn ín,

Ọlọ́run baba mi, èmi ó gbé e ga.

3 Ológun ni Olúwa,

Olúwa ni orúkọ rẹ,

4 kẹ̀kẹ́ ogun Farao àti ogun rẹ̀

ni ó wọ inú Òkun.

Àwọn ọmọ-ogun Farao jáfáfá jùlọ

ni ó sínú Òkun Pupa.

5 Ibú omi wọ́n mọ́lẹ̀;

wọ́n ìsàlẹ̀ omi òkun òkúta.

6 "Ọwọ́ ̀tún rẹ, Olúwa,

pọ̀ agbára.

Ọwọ́ ̀tún rẹ, Olúwa,

fọ́ àwọn ̀túútúú.

7 "Nínú agbára ńlá rẹ ti ó tóbi

ìwọ bi àwọn ti ó dìde ṣubú.

Ìwọ rán ìbínú gbígbóná rẹ;

ó run wọ́n àgémọ́lẹ̀ ìdí koríko.

8 Pẹ̀èémí imú rẹ ni

omi fi ń wọ́jọ pọ̀.

Ìṣàn omi dìde dúró odi;

ibú omi dìpọ̀ láàrín Òkun.

9 ̀ń gbéraga, ó ń ,

Èmi ó lépa wọn, èmi ó wọn.

èmi ó pín ìkógun;

èmi ó tẹ́ ìfẹ́kúfẹ̀́ mi lọ́run lára wọn.

Èmi yóò fa idà mi yọ,

ọwọ́ mi yóò pa wọ́n run.

10 Ìwọ fẹ́ èémí rẹ,

òkun ru wọ́n mọ́lẹ̀.

Wọ́n òjé

ni àárín omi ńlá.

11 Ta ni nínú àwọn òrìṣà

dàbí rẹ, Olúwa?

Ta dàbí rẹ:

títóbi,

mímọ́ Ẹlẹ́ni yìn,

ń ṣe ohun ìyanu?

12 "Ìwọ na apá ̀tún rẹ,

ilẹ̀ si gbé wọn .

13 Nínú ìfẹ́ rẹ ti í sákí Ìwọ ṣe amọ̀

àwọn ènìyàn náà Ìwọ ti padà.

Nínú agbára rẹ Ìwọ yóò tọ́ wọn,

lọ ibi ìjókòó rẹ mímọ́.

14 Orílẹ̀-èdè yóò gbọ́ wọn yóò wárìrì.

Ìkáàánú yóò mi àwọn ènìyàn Filistia.

15 Ìbẹ̀yóò àwọn ìjòyè Edomu,

àwọn olórí Moabu yóò wárìrì.

Àwọn ènìyàn Kenaani yóò yọ́ dànù.

16 Ìbẹ̀bojo yóò ṣubú wọ́n, nítorí

nína títóbi apá rẹ̀

wọn yóò dúró jẹ́́ láì mira i òkúta,

títí àwọn ènìyàn rẹ yóò fi rékọjá, Olúwa,

títí àwọn ènìyàn o ti yóò fi rékọjá.

17 Ìwọ yóò wọn láti gbìn wọ́n

ni orí òkè ti ìwọ jogún,

ibi ti ìwọ ṣe fún ara rẹ, Olúwa.

Láti máa gbé ibi mímọ́ ti ìwọ fi ọwọ́ rẹ gbé kalẹ̀, Olúwa.

18 "Olúwa yóò jẹ ọba

láé àti láéláé."

19 Nígbà ti ẹṣin Farao, kẹ̀kẹ́ ogun àti àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀ wọ inú Òkun, Olúwa omi òkun padà wọ́n mọ́lẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli rìn lórí ìyàngbẹ ilẹ̀ la òkun kọjá. 20 Miriamu wòlíì obìnrin, arábìnrin Aaroni, ohun èlò orin ni ọwọ́ rẹ̀, gbogbo àwọn obìnrin jáde tẹ̀e pẹ̀ìlù òun ijó. 21 Miriamu kọrin wọn báyìí ,

"kọrin Olúwa,

nítorí òun ni ológo jùlọ.

Ẹṣin àti ẹni ó gùn ún,

ni òun bi ṣubú sínú Òkun."

Omi Mara àti Elimu

22 Nígbà náà ni Mose ṣe amọ̀àwọn ènìyàn Israẹli jáde láti Òkun Pupa lọ sínú ijù Ṣuri. Wọ́n lọ ìrìn ọjọ́ mẹ́ta sínú ijù náà, wọn omi. 23 Nígbà wọ́n Mara, wọn mu omi Mara nítorí omi náà korò. (Nítorí náà ni a ṣe pe ibẹ̀ ni Mara: ibi ìkorò.) 24 Àwọn ènìyàn ń kùn Mose , "ni àwa yóò mu?"

25 Mose pe Olúwa, Olúwa fi igi kan hàn án, ó sọ igi náà sínú omi, omi náà dùn.

Níbẹ̀ ni Olúwa ti gbé ìlànà àti òfin kalẹ̀ fún wọn, níbẹ̀ ni ó ti dán wọn . 26 Ó , "ìwọ fetísílẹ̀ dáradára òfin Olúwa Ọlọ́run, ti ìwọ ṣe ohun ó tọ́ ni ojú rẹ̀, ti ìwọ tẹ̀ohun ó pàṣẹ, ti ìwọ si pa ìlànà rẹ̀ mọ́. Èmi yóò jẹ́ èyíkéyìí nínú àwọn ààrùn wọ̀n-ọn-nì ti mo sórí àwọn ará Ejibiti ara rẹ, nítorí Èmi ni Olúwa ti ó láradá."

27 Nígbà ti wọ́n Elimu, níbi ti kànga omi méjìlá àti àádọ́rin ̀pẹ gbé , wọ́n pàgọ́ síbẹ̀ ni etí omi.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-