Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 17

Omi láti inú àpáta

1 17.1-7: Nu 20.2-13. Gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli si gbéra láti jáde kúrò láti aginjù Sini wọ́n ń lọ láti ibi kan de ibi kan gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ. Wọ́n pàgọ́ Refidimu, ṣùgbọ́n omi fún àwọn ènìyàn láti . 2 Àwọn ènìyàn sọ̀ fún Mose, wọ́n , "Fún wa ni omi mu."

Mose wọn lóhùn , "Èéṣe ti ̀yin fi ń mi ? Èéṣe ti ̀yin fi ń dán Olúwa ?"

3 17.3: Ek 14.12; 16.3. Ṣùgbọ́n òǹgbẹ ń gbẹ àwọn ènìyàn, wọ́n ń kùn Mose, wọ́n , "Èéṣe ìwọ fi wa jáde kúrò Ejibiti láti òǹgbẹ pa àwa, àwọn ọmọ wa àti ohun ̀sìn wa ku fún òǹgbẹ."

4 Nígbà náà ni Mose gbé ohùn rẹ̀ sókè Olúwa , "ni èmi ó ṣe fún àwọn ènìyàn yìí? Wọ́n múra tan láti sọ mi ni òkúta."

5 Olúwa Mose lóhùn , "Máa lọ síwájú àwọn ènìyàn, nínú àwọn àgbàgbà Israẹli pẹ̀rẹ, ̀ìwọ fi lu odò Naili lọ́wọ́ ó máa lọ. 6 Èmi yóò dúró ni ibẹ̀ ni orí àpáta ni Horebu. Ìwọ ó lu àpáta, omi yóò jáde nínú rẹ̀ fún àwọn ènìyàn láti mu." Mose ṣe bẹ́̀ ni iwájú àwọn àgbàgbà Israẹli. 7 Ó sọ orúkọ ibẹ̀ ni Massa17.7 Massatúmọ̀ sí ìdánwò àti Meriba17.7 Meribatúmọ̀ sí kíkùn, nítorí àwọn ọmọ Israẹli sọ̀, wọ́n dán Olúwa , wọ́n , "Ǹjẹ́ Olúwa ń bẹ láàrín wa tàbí ?"

A ṣẹ́gun àwọn ará Amaleki

8 Àwọn ara Amaleki jáde, wọ́n dìde ogun àwọn ọmọ Israẹli ni Refidimu. 9 Mose sọ fún Joṣua , "Yàn lára àwọn ọkùnrin fún wa, wọn ó jáde lọ àwọn ará Amaleki . ̀la, èmi yóò dúró ni orí òkè pẹ̀̀Ọlọ́run ọwọ́ mi."

10 Joṣua ṣe Mose ti fún un, ó àwọn ará Amaleki jagun; nígbà Mose, Aaroni àti Huri lọ orí òkè náà. 11 Níwọ́n ìgbà Mose gbé apá rẹ̀ sókè, Israẹli n borí ṣùgbọ́n nígbà ó rẹ apá rẹ̀ sílẹ̀, Amaleki a borí. 12 Ṣùgbọ́n apá ń ro Mose, wọ́n òkúta, wọ́n fi abẹ́ rẹ̀, ó jókòó òkúta náà; Aaroni àti Huri mu apá rẹ̀, ̀kan apá ̀tún àti èkejì ni apá òsì; apá rẹ̀ méjèèjì dúró gangan títí di ìgbà ti oòrùn wọ. 13 Joṣua fi ojú idà ṣẹ́gun àwọn ará Amaleki.

14 17.14: De 25.17-19; 1Sa 15.2-9. Olúwa sọ fun Mose . "Kọ èyí inú ìwé fún ìrántí, o sọ fún Joṣua pẹ̀; nítorí èmi yóò pa ìrántí Amaleki run pátápátá kúrò lábẹ́ ̀run."

15 Mose tẹ́ pẹpẹ kan, ó sọ orúkọ pẹpẹ náà Olúwa ni Àsíá mi. 16 Ó , "A gbé ọwọ́ sókè ìtẹ́ Olúwa. Olúwa yóò Amaleki jagun láti ìran ìran."

Veja também