Publicidade

Êxodo 18

Jetro bẹ Mose

1 Jetro, àlùfáà Midiani, àna Mose, gbọ́ gbogbo ohun Ọlọ́run ti ṣe fún Mose àti fún Israẹli àwọn ènìyàn rẹ̀, àti Olúwa ti àwọn ènìyàn Israẹli jáde láti Ejibiti .

2 Nígbà náà ni Jetro mu aya Mose í ṣe Sippora padà lọ sọ́dọ̀ rẹ (nítorí ó ti a padà ̀dọ̀ baba rẹ̀ tẹ́lẹ̀), 3 18.3,4: Ap 7.29.Òun àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ méjèèjì. Orúkọ àkọ́ń jẹ́ Gerṣomu; nítorí Mose , "Èmi ń ṣe àlejò ni ilẹ̀ àjèjì." 4 Èkejì ń jẹ́ Elieseri; ó , "Ọlọ́run baba mi ni alátìlẹ́yìn mi, ó gbà kúrò lọ́wọ́ idà Farao."

5 Jetro, àna Mose, òun àti aya àti àwọn ọmọ Mose tọ̀ ́ nínú aginjù ó tẹ̀, nítòsí òkè Ọlọ́run. 6 Jetro ti ránṣẹ́ Mose , "Èmi Jetro, àna rẹ, ni mo ń bọ̀ ̀dọ̀ rẹ, èmi àti aya àti àwọn ọmọkùnrin rẹ méjèèjì."

7 Mose jáde lọ pàdé àna rẹ̀, ó tẹríba fún un, ó fi ẹnu ó ni ẹnu. Wọ́n béèrè àlàáfíà ara wọn, wọ́n wọ inú àgọ́ lọ. 8 Mose sọ fún àna rẹ̀ nípa ohun gbogbo ti Olúwa ṣe Farao àti àwọn ará Ejibiti nítorí Israẹli. Ó sọ nípa gbogbo ìṣòro wọn pàdé ̀wọn àti Olúwa ti gbà wọ́n .

9 Inú Jetro dùn láti gbọ́ gbogbo ohun rere ti Olúwa ṣe fún Israẹli, ẹni ó wọ́n jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti. 10 Jetro , "Ìyìn ni fún Olúwa, ẹni ó gba yín kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Ejibiti àti lọ́wọ́ Farao, ẹni ó gba àwọn ènìyàn kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Ejibiti. 11 Mo mọ nísinsin yìí Olúwa tóbi ju gbogbo àwọn òrìṣà lọ; nítorí ti ó gba àwọn ènìyàn rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ ìgbéraga àti ìkà àwọn ará Ejibiti." 12 Jetro, àna Mose, ẹbọ sísun àti ẹbọ fún Ọlọ́run. Aaroni àti gbogbo àgbàgbà Israẹli láti àna Mose jẹun iwájú Ọlọ́run.

13 ọjọ́ kejì, Mose jókòó láti máa ṣe ìdájọ́ fún àwọn ènìyàn gẹ́gẹ́ ìṣe rẹ̀; àwọn ènìyàn dúró ti Mose fún ìdájọ́ wọn láti òwúrọ̀ títí di ìrọ̀lẹ́. 14 Nígbà àna Mose àkókò ti èyí ń gba ti pọ̀ àti ti àwọn ènìyàn ti ń dúró pẹ́ , ó , "ni èyí ìwọ ń ṣe àwọn ènìyàn? Èéṣe ti ìwọ nìkan jókòó gẹ́gẹ́ adájọ́, nígbà àwọn ènìyàn wọ̀nyí dúró láti òwúrọ̀ di ìrọ̀lẹ́?"

15 Mose a lóhùn , "Nítorí àwọn ènìyàn ń tọ̀ láti mọ́ ìfẹ́ Ọlọ́run. 16 Nígbà wọ́n ẹjọ́, wọn a un tọ̀ , èmi a ṣe ìdájọ́ láàrín ẹnìkínní àti ẹnìkejì, èmi a máa wọn mọ òfin àti ìlànà Ọlọ́run."

17 Àna Mose a lóhùn , "Ohun o ń ṣe yìí dára. 18 Ìwọ àti àwọn ènìyàn ti ń tọ̀ ́ yìí yóò ara yín agara; iṣẹ́ yìí pọ̀fún , ìwọ nìkan a ṣe. 19 Nísinsin yìí, fetísílẹ̀ mi, èmi yóò gbà ́ ni ìmọ̀ràn, Ọlọ́run yóò pẹ̀rẹ. Ìwọ gbọdọ̀ jẹ́ aṣojú àwọn ènìyàn wọ̀nyí níwájú Ọlọ́run, ìwọ yóò èdè-àìyedè iwájú rẹ̀. 20 Kọ́ wọn òfin àti ìlànà Ọlọ́run, fi ̀igbe ayé ìwà-bí-Ọlọ́run hàn wọ́n àti iṣẹ́ wọn yóò máa ṣe. 21 Ṣa àwọn ó kún ojú òsùwọ̀n nínú gbogbo àwọn ènìyàn, àwọn bẹ̀Ọlọ́run, ti wọ́n jẹ́ olóòtítọ́, wọ́n kórìíra ìrẹ́jẹ; yàn wọ́n ṣe olórí, lórí ẹgbẹ̀rún ẹgbẹ̀rún, ọgọ́rùn-ún ọgọ́rùn-ún, àádọ́ta-dọ́ta àti mẹ́wàá mẹ́wàá. 22 Jẹ́ wọn ó máa ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn ni gbogbo ìgbà, ṣùgbọ́n jẹ́ wọn ẹjọ́ ó nira fún wọn láti tọ̀ ́ ; wọn ó máa ẹjọ́ kéékèèké. Èyí ni yóò iṣẹ́ rẹ rọrùn, wọn yóò máa ràn ́ lọ́wọ́ lórí ìdájọ́ ṣíṣe. 23 ìwọ ṣe èyí, Ọlọ́run fi àṣẹ i fún bẹ́̀, àárẹ̀ tètè mu , àwọn ènìyàn wọ̀nyí yóò padà lọ ilé wọn ni àlàáfíà."

24 Mose fetísílẹ̀ àna rẹ̀, ó ṣe ohun gbogbo ó fún un. 25 Mose yan àwọn ènìyàn wọ́n kún ojú òsùwọ̀n nínú gbogbo Israẹli; ó fi wọ́n jẹ olórí àwọn ènìyàn, olórí ẹgbẹẹ̀rún, olórí ̀rọ̀̀rún, olórí àràádọ́ta, àti olórí mẹ́wàá mẹ́wàá. 26 Wọ́n ń ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn ìgbà gbogbo. Wọ́n ń ẹjọ́ le tọ Mose ; ṣùgbọ́n wọ́n ń ẹjọ́ le fúnra wọn.

27 Mose jẹ́ àna rẹ̀ lọ ̀rẹ̀, Jetro padà ilẹ̀ rẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-