Pular para o conteúdo
Publicidade

Êxodo 2

Ìbí Mose

1 Ó ṣe, ọkùnrin ará ilé Lefi kan fẹ́ ọmọbìnrin ará Lefi kan ni ìyàwó. 2 2.2: Ap 7.20; Hb 11.23.Obìnrin náà lóyún, ó ọmọkùnrin kan. Nígbà ó í ọmọ náà rẹwà, ó gbé ọmọ náà pamọ́ fún oṣù mẹ́ta. 3 Ṣùgbọ́n nígbà le è gbé e pamọ́ mọ́, ó fi ewé papirusi hun apẹ̀rẹ̀, ó fi ̀àti òjé igi sán apẹ̀rẹ̀ náà. Ó tẹ́ ọmọ náà sínú rẹ̀, ó gbe é inú eèsún ni etí odò Naili. 4 Arábìnrin rẹ̀ dúró ni òkèèrè láti wo ohun yóò ṣẹlẹ̀ ọmọ náà.

5 2.5,10: Ap 7.21. Nígbà náà ni ọmọbìnrin Farao sọ̀kalẹ̀ etí odò Naili láti wẹ̀, àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ ń rìn ni etí bèbè odò. Ó ri apẹ̀rẹ̀ náà ni àárín eèsún, ó rán ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ obìnrin kan láti lọ gbé e , 6 ó ṣí i, ó ọmọ náà. Ọmọ náà ń sọkún, àánú ọmọ náà ṣe é. Ó , "̀kan nínú àwọn ọmọ Heberu ni èyí."

7 Nígbà náà ni arábìnrin rẹ̀ béèrè lọ́wọ́ ọmọbìnrin Farao , "Ṣé èmi lọ ̀kan lára àwọn obìnrin Heberu fún láti tọ́ọmọ náà?"

8 Ó dáhùn , "Bẹ́̀ ni; lọ." Arábìnrin náà lọ, ó pe ìyá ọmọ náà . 9 Ọmọbìnrin Farao fún un , "Gba ọmọ yìí o tọ́rẹ̀ fún mi, èmi yóò san owó iṣẹ́ ̀ rẹ fún ." Ọmọbìnrin náà gbé ọmọ náà lọ, ó tọ́rẹ̀. 10 Nígbà ọmọ náà dàgbà, ó un tọ ọmọbìnrin Farao , ó di ọmọ rẹ̀. Ó pe orúkọ rẹ̀ Mose, ó , "Nítorí mo á jáde nínú omi."

Mose sálọ Midiani

11 2.11: Ap 7.23; Hb 11.24. ọjọ́ kan, nígbà Mose ti dàgbà, ó jáde lọ ibi ti àwọn ènìyàn rẹ̀ , ó ń wọ́n lẹ́nu iṣẹ́ líle wọn, ó ri ará Ejibiti ń lu ará Heberu, ̀kan nínú àwọn ènìyàn rẹ̀. 12 2.12: Ap 7.24.Ó wo ìhín, ó wo ̀hún, nígbà ẹnìkankan, ni ó pa ará Ejibiti náà, ó ó mọ́ inú iyanrìn. 13 ọjọ́ kejì, ó jáde lọ, ó àwọn ará Heberu méjì wọ́n ń . Ó béèrè lọ́wọ́ èyí ó jẹ̀bi , "Èéṣe ìwọ fi ń lu Heberu arákùnrin rẹ?"

14 2.14: Ap 7.27,28. Ọkùnrin náà dáhùn , "Ta ni ó fi ́ jẹ olórí àti onídàájọ́ lórí wa? Ṣé ìwọ fẹ́ pa o ti pa ará Ejibiti?" Nígbà náà ni ̀ba Mose, ó , "Lóòótọ́ ni ̀ràn yìí ti di mọ̀."

15 2.15,22: Ap 7.29. Nígbà ti Farao gbọ́ nípa èyí, ó ̀láti pa Mose, ṣùgbọ́n Mose kúrò àrọ́wọ́o Farao, ó lọ Midiani láti máa gbé, nígbà ó bẹ̀, ó jókòó ni ̀a kànga kan. 16 Ó ṣe, àlùfáà Midiani kan ni àwọn ọmọbìnrin méje, wọn láti pọn omi kún ọpọ́n ìmumi fún ẹran ̀sìn baba wọn. 17 Àwọn darandaran kan , wọ́n wọn sẹ́yìn, ṣùgbọ́n Mose dìde láti gbà wọ́n sílẹ̀ àti láti ràn wọ́n lọ́wọ́ láti fún ẹran wọn omi.

18 Nígbà ti àwọn ọmọbìnrin náà padà ̀dọ̀ Reueli baba wọn, ó béèrè lọ́wọ́ wọn , "Èéṣe ̀yin fi tètè ni òní?"

19 Wọ́n a lóhùn , "Ará Ejibiti kan ni ó gbà sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn darandaran, ó tilẹ̀ ràn lọ́wọ́ láti fa omi àti láti fún agbo ẹran omi."

20 Ó sọ fún àwọn ọmọbìnrin rẹ̀, "Níbo ni ó ? Èéṣe ti fi fi ọkùnrin náà sílẹ̀? é jẹun."

21 Mose gbà láti dúró lọ́dọ̀ ọkùnrin náà, ẹni o fi Sippora, ọmọbìnrin rẹ̀ fún Mose láti fi ṣe aya. 22 Ó ọmọkùnrin kan ó pe orúkọ rẹ̀ Gerṣomu, ó , "Èmi ń ṣe àtìpó ilẹ̀ àjèjì."

23 Lẹ́yìn ìgbà pípẹ́, ọba Ejibiti . Àwọn ará Israẹli ń kérora oko ẹrú wọn, wọ́n ń fún ìrànlọ́wọ́ nítorí oko ẹrú wọ́n , igbe wọ́n ̀dọ̀ Ọlọ́run. 24 2.24: Ap 7.34.Ọlọ́run gbọ́ igbe wọn, Ó rántí májẹ̀rẹ̀ pẹ̀Abrahamu, Isaaki àti pẹ̀Jakọbu. 25 Nítorí náà, Ọlọ́run bojú wo àwọn ará Israẹli, Ó láti gbà wọ́n sílẹ̀.

Veja também