Publicidade

Êxodo 20

Òfin mẹ́wàá

1 Ọlọ́run sọ gbogbo ̀rọ̀ yìí ,

2 20.2-17: De 5.6-21. "Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, ó un yín jáde láti ilẹ̀ Ejibiti, láti oko ẹrú jáde .

3 20.3: Ek 20.23; De 5.7. "Ìwọ gbọdọ̀ ọlọ́run mìíràn pẹ̀mi.

4 20.4: Ek 20.23; 34.17; Le 19.4; 26.1; De 4.15-19; 5.8; 27.15. Ìwọ gbọdọ̀ ṣe ère fún ara yín, tàbí àwòrán ohun kan ń bẹ òkè ̀run, tàbí ti ohun kan ń bẹ ìsàlẹ̀ ilẹ̀, tàbí ti ohun kan ń bẹ nínú omi ìsàlẹ̀ ilẹ̀. 5 20.5,6: Ek 23.24; 34.6,7,14; De 4.24; 5.9,10; 7.9.Ìwọ gbọdọ̀ tẹ orí ara rẹ ba fún wọn, bẹ́̀ ni ìwọ gbọdọ̀ sìn wọ́n; nítorí Èmi Olúwa Ọlọ́run rẹ, Ọlọ́run owú ni , ń bẹ ̀ṣẹ̀ àwọn baba lára àwọn ọmọ, láti ìran kẹta títí ̀kẹrin nínú àwọn ó kórìíra mi. 6 Èmi a máa fi àánú hàn ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn ó fẹ́ mi, wọ́n ń pa òfin mi mọ́.

7 20.7: Le 19.12; De 5.11. ṣe ṣi orúkọ Olúwa Ọlọ́run yín , torí ẹnikẹ́ni o ṣi orúkọ rẹ̀ yóò lọ láìjẹ̀bi.

8 20.8: Ek 23.12; 31.12-17; 34.21; 35.2,3; Le 19.3; De 5.12-15. Rántí ọjọ́ ìsinmi láti á mímọ́. 9 Ọjọ́ mẹ́ni ìwọ yóò fi ṣiṣẹ́, ìwọ ó ṣe gbogbo iṣẹ́ rẹ, 10 ṣùgbọ́n ọjọ́ keje ni ọjọ́ ìsinmi Olúwa Ọlọ́run rẹ: nínú rẹ̀ ìwọ gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ kan: ìwọ, àti ọmọ rẹ ọkùnrin àti ọmọ rẹ obìnrin, ọmọ ̀dọ̀ rẹ ọkùnrin àti ọmọ ̀dọ̀ rẹ obìnrin, àti ẹran ̀sìn rẹ, àti àlejò rẹ, ń bẹ nínú ibodè rẹ. 11 Nítorí ọjọ́ mẹ́ni Olúwa ̀run àti ayé, òkun àti ohun gbogbo ń bẹ nínú wọn, ó sinmi ọjọ́ keje: nítorí náà ni Olúwa ṣe bùkún ọjọ́ ìsinmi ó á mímọ́.

12 20.12-16: Mt 19.18,19; Mk 10.19; Lk 18.20. 20.12: Le 19.3; De 5.16; Mt 15.4; Mk 7.10; Ef 6.2. Bọ̀wọ̀ fún baba òun ìyá rẹ, ọjọ́ rẹ ó pẹ́ orí ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ fi fún .

13 20.13: Gẹ 9.6; Ek 21.12; Le 24.17; De 5.17; Mt 5.21; Jk 2.11. 20.13-17: Ro 13.9. Ìwọ gbọdọ̀ pànìyàn.

14 20.14: Le 20.10; De 5.18; Mt 5.27; Ro 7.7. Ìwọ gbọdọ̀ ṣe panṣágà.

15 20.15: Le 19.11; De 5.19. Ìwọ gbọdọ̀ jalè.

16 20.16: Ek 23.1; De 5.20. Ìwọ gbọdọ̀ jẹ́rìí èké ẹnìkejì rẹ.

17 20.17: De 5.21; Ro 7.7. Ìwọ gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò ilé ẹnìkéjì rẹ. Ìwọ gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò aya ẹnìkéjì rẹ, ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ ọkùnrin àti ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ obìnrin, akọ màlúù rẹ̀ àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ àti ohun gbogbo í ṣe ti ẹnìkéjì rẹ."

18 Nígbà àwọn ènìyàn náà mọ̀nàmọ́wọ́n gbọ́ ohùn ìpè àti èéfín ń láti orí òkè, wọ́n gbọ́ sísán àrá, dídún ìpè kíkankíkan; wọ́n dúró òkèrè wọ́n ń gbọ̀n ṣìgàṣìgà fún ìbẹ̀. 19 Wọ́n fún Mose , "Ìwọ fúnra rẹ̀ máa wa sọ̀rọ̀, àwa yóò gbọ́. ṣe jẹ́ Ọlọ́run fúnra rẹ̀ ó wa sọ̀rọ̀, bẹ́̀ kọ́, àwa yóò ."

20 Mose sọ fún àwọn ènìyàn náà , "bẹ̀. Ọlọ́run láti dán an yín , ̀Ọlọ́run ó máa ara yín, ̀yin ó ṣe ṣẹ̀."

21 Àwọn ènìyàn dúró òkèèrè nígbà Mose súnmọ́ ibi òkùnkùn biribiri níbi Ọlọ́run .

22 Olúwa sọ fún Mose , "Sọ àwọn nǹkan wọ̀nyí fún àwọn ará Israẹli, ̀yin ti i fúnra yín èmi ti a yín sọ̀rọ̀ láti ̀run . 23 20.23: Ek 20.3,4; 34.17; De 27.15.̀yin gbọdọ̀ sin ọlọ́run mìíràn pẹ̀mi: ̀yin gbọdọ̀ rọ ọlọ́run fàdákà tàbí ọlọ́run wúrà fún ara yín.

24 20.24: Ek 27.1-8; De 12.5; 26.2. " Pẹpẹ erùpẹ̀ ni ìwọ mọ fún mi. orí pẹpẹ yìí ni ìwọ ti máa ẹbọ sísun rẹ mi àti ẹbọ àlàáfíà rẹ, àgùntàn rẹ, ewúrẹ́ àti akọ màlúù rẹ. ibi gbogbo mo gbé fi ìrántí orúkọ mi , èmi yóò máa tọ̀ ́ , èmi yóò máa bùkún níbẹ̀. 25 20.25: De 27.5-7; Jo 8.31.ìwọ ṣe pẹpẹ òkúta fún mi, ṣe fi òkúta a ṣe lọ́ṣọ̀́ kọ́ , nítorí ìwọ lo ohun ọnà rẹ lórí rẹ̀, ìwọ sọ di àìmọ́. 26 Ìwọ gbọdọ̀ gun àkàsọ̀ lọ ibi pẹpẹ mi, àwọn ènìyàn ba à máa wo ìhòhò rẹ láti abẹ́ aṣọ ìwọ wọ̀ nígbà ìwọ ń gòkè lọ ibi pẹpẹ.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-