Publicidade

Êxodo 25

Ọrẹ ẹbọ fún àgọ́

1 25.1: Ek 35–40. Olúwa fún Mose , 2 25.2-8: Ek 35.4-9."Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli wọn ọrẹ fún mi, ìwọ yóò gba ọrẹ náà fún mi ni ọwọ́ ọkùnrin kọ̀̀kan ti ọkàn rẹ fẹ́ láti fi fún mi.

3 "Wọ̀nyí ni ọrẹ ti ìwọ yóò gbà ni ọwọ́ wọn:

"wúrà, fàdákà àti idẹ;

4 aṣọ aláró, elése àlùkò, òdòdó, ̀gbọ̀;

irun ewúrẹ́.

5 Awọ àgbò a rẹ pupa àti awọ ewúrẹ́ igbó;

igi kasia;

6 Òróró olifi fún iná títàn;

òróró olóòórùn dídùn fún ìtasórí àti fún tùràrí olóòórùn dídùn;

7 àti òkúta óníkìsì àti òkúta olówó iyebíye ti a fi ṣe ̀ṣọ́ ara ̀efodu àti ̀ìgbàyà.

8 "Nígbà náà ni ìwọ yóò jẹ́ wọn kọ́ ibi mímọ́ fún mi. Èmi yóò máa gbé àárín wọn. 9 Gẹ́gẹ́ gbogbo èyí ti mo fihàn ́, nípa àpẹẹrẹ àgọ́, àti àpẹẹrẹ gbogbo ohun èlò inú rẹ̀, bẹ́̀ ni ̀yin ó ṣe é.

Àpótí ̀

10 25.10-22: Ek 37.1-9. "Wọn yóò fi igi ṣittimu ṣe àpótí, ìgbọ̀nwọ́ méjì ààbọ̀ ni gígùn rẹ̀, ìgbọ̀nwọ́ kan ààbọ̀ ni fífẹ̀ rẹ̀, ìgbọ̀nwọ́ kan ààbọ̀ ni gíga rẹ̀. 11 Ìwọ ó fi ojúlówó wúrà, ó inú àti òde, ìwọ ó fi wúrà gbá etí rẹ̀ yíká. 12 Ìwọ ó da òrùka wúrà mẹ́rin fún. Ìwọ ó fi wọ́n igun mẹ́rẹ̀̀rin ẹsẹ̀ rẹ̀, òrùka wúrà méjì yóò ̀gbẹ́ kìn-ín-ní, òrùka wúrà méjì yóò ẹgbẹ́ kejì. 13 Ìwọ ó fi igi kasia ṣe ̀mẹ́rin, ìwọ ó fi wúrà wọ́n. 14 Ìwọ ó fi ̀náà bọ òrùka ̀gbẹ́ kọ̀̀kan àpótí ̀náà láti fi gbé e. 15 Òpó náà yóò nínú òrùka lára àpótí ̀; a yọ wọ́n kúrò. 16 Nígbà náà ni ìwọ yóò fi ̀ti èmi yóò fi fún sínú àpótí náà.

17 "Ìwọ ó fi ojúlówó wúrà ṣe ìtẹ́ àánú; ìgbọ̀nwọ́ méjì àti ààbọ̀ gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ kan àti ààbọ̀ fífẹ̀. 18 Ìwọ ó ṣe kérúbù méjì láti inú wúrà a fi òòlù igun ìtẹ́ àánú náà. 19 Ìwọ ó ṣe kérúbù kan igun kìn-ín-ní àti kérúbù kejì igun kejì, kérúbù náà jẹ́ irú kan náà igun méjèèjì pẹ̀ìbòrí wọn. 20 Àwọn kérúbù na ìyẹ́ apá wọn sókè, wọn yóò fi ìyẹ́ apá wọn ṣe ibòòji orí ìtẹ́ àánú. Àwọn kérúbù náà yóò kọ ojú ara wọn, wọn yóò máa wo ̀kánkán ìtẹ́. 21 Gbé ọmọrí orí àpótí ̀o fi ̀èyí èmí yóò fi fún sínú àpótí ̀. 22 Níbẹ̀, ni òkè ìtẹ́, àárín kérúbù méjèèjì ti ó ni orí àpótí ̀ni èmi yóò ti pàdé rẹ, ti èmi yóò fún àwọn òfin mi fún àwọn ọmọ Israẹli.

Tábìlì

23 25.23-30: Ek 37.10-15. "Fi igi kasia kan tábìlì: ìgbọ̀nwọ́ méjì gígùn ìgbọ̀nwọ́ kan fífẹ̀, ìgbọ̀nwọ́ kan àti ààbọ̀ gíga. 24 Ìwọ ó fi ojúlówó wúrà ó, ìwọ ó ṣe ìgbátí wúrà i . 25 Ìwọ ṣe etí kan ìbú àtẹ́lẹwọ́ i yíká, ó ṣe ìgbátí wúrà etí rẹ̀ . 26 Ìwọ ó da òrùka wúrà mẹ́rin fún tábìlì náà, ìwọ ó fi òrùka kọ̀̀kan igun mẹ́rẹ̀̀rin ó ẹsẹ̀ rẹ̀ mẹ́rẹ̀̀rin. 27 abẹ́ ìgbátí náà ni àwọn òrùka náà yóò fún ibi ̀láti máa fi gbé tábìlì náà. 28 Ìwọ ó fi igi kasia ṣe àwọn ̀, ìwọ ó fi wúrà wọ́n, láti máa fi wọ́n gbé tábìlì náà. 29 Ìwọ ó fi ojúlówó wúrà ṣe àwo àti ṣíbí rẹ̀, o ṣe àwokòtò àti ago pẹ̀fún dída ọrẹ jáde. 30 25.30: Ek 39.36; 40.23; Le 24.5-9.Gbé àkàrà ìfihàn orí tábìlì yìí, ó le iwájú mi ni gbogbo ìgbà.

̀fìtílà

31 25.31-40: Ek 37.17-24. "Ìwọ ó ojúlówó wúrà, ú dáradára, ṣe ̀fìtílà kan, ìsàlẹ̀ àti apá rẹ̀, kọ́̀rẹ̀ ti ó dàbí òdòdó, ìṣọ àti ìtànná rẹ̀ yóò jẹ́ ara kan náà pẹ̀rẹ̀. 32 ̀ka mẹ́ni yóò yọ ̀gbẹ́ ̀fìtílà: mẹ́ta ̀gbẹ́ kìn-ín-ní mẹ́ta ni ̀gbẹ́ kejì. 33 Àwo mẹ́ta ni a ṣe ìtànná almondi, ó ṣọ ó tanná ni yóò ni ̀ka kan, mẹ́ta yóò ̀ka kejì, àti bẹ́̀ fún àwọn ̀ka mẹ́fẹ̀̀ó jáde lára ̀fìtílà. 34 ara ̀fìtílà ni àwo mẹ́rin ti a ṣe gẹ́gẹ́ òdòdó almondi ti ó ni ìṣọ àti ìtànná yóò . 35 Irúdì kan yóò abẹ́ ̀ka rẹ̀ méjì àkọ́kọ́ ó yọ lára ̀fìtílà, irúdì kejì ó abẹ́ ̀ka rẹ̀ méjì kejì, irúdì kẹta yóò abẹ́ ̀ka rẹ̀ méjì kẹta, ̀ka mẹ́àpapọ̀. 36 Irúdì wọn àti ̀ka wọn ó bákan náà, gbogbo rẹ̀ ó jẹ́ lílù ojúlówó wúrà.

37 "Nígbà náà ni ìwọ yóò ṣe fìtílà méje. Ìwọ yóò gbe ka orí rẹ̀, wọn ó máa ṣe ìmọ́lẹ̀ iwájú rẹ̀. 38 Àti alumagaji rẹ̀, àti àwo alimagaji rẹ̀, ó jẹ́ kìkì wúrà. 39 Tálẹ́ǹtì kìkì wúrà ni ó fi ṣe é, pẹ̀gbogbo ohun èlò wọ̀nyí. 40 25.40: Ap 7.44; Hb 8.5.Kíyèsí i, ìwọ ó ṣe wọ́n gẹ́gẹ́ àpẹẹrẹ wọn, ti a fi hàn ́ ni orí òkè.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-