Publicidade

Êxodo 34

Òkúta wàláà tuntun

1 Olúwa sọ fún Mose , "E òkúta wàláà méjì jáde i ti àkọ́kọ́, Èmi yóò kọ àwọn ̀rọ̀ ìwé lára àkọ́kọ́ ìwọ ti fọ́ sára wọn. 2 Múra òwúrọ̀, o sórí òkè Sinai. o fi ara rẹ hàn lórí òkè náà. 3 Ẹnikẹ́ni gbọdọ̀ pẹ̀rẹ tàbí a wọn lórí òkè náà; bẹ́̀ ni agbo àgùntàn tàbí ọwọ́ ẹran ṣe jẹ níwájú òkè náà."

4 Bẹ́̀ Mose gbẹ́ òkúta wàláà méjì ti àkọ́kọ́, ó gun orí òkè Sinai lọ kùtùkùtù òwúrọ̀, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pa á láṣẹ fún un; Ó gbé òkúta wàláà méjèèjì náà ọwọ́ rẹ̀. 5 Nígbà náà ni Olúwa sọ̀kalẹ̀ nínú àwọsánmọ̀, ó dúró níbẹ̀ pẹ̀rẹ̀, ó pòkìkí orúkọ Olúwa. 6 34.6: Nu 14.18; Ne 9.17; Sm 86.15; 103.8; 145.8; Jn 4.2.Ó kọjá níwájú Mose, ó ń , "Olúwa, Olúwa, Ọlọ́run aláàánú àti olóore-ọ̀fẹ́, Ẹni ó lọ́ra láti bínú, ó pọ̀ ìfẹ́ àti olóòtítọ́, 7 Ẹni ó ń pa ìfẹ́ mọ́ fún ẹgbẹ̀rún (1,000), ó ń dáríjì àwọn ẹni búburú, àwọn ti ń ṣọ̀tẹ̀ àti ẹlẹ́ṣẹ̀. Síbẹ̀ í fi àwọn ẹlẹ́bi sílẹ̀ láìjìyà; Ó ń fi ìyà jẹ ọmọ àti àwọn ọmọ wọn fún ̀ṣẹ̀ àwọn baba ìran kẹta àti ̀kẹrin."

8 Mose foríbalẹ̀ lẹ́̀kan náà ó sìn. 9 Ó , "Olúwa, èmi ojúrere rẹ, nígbà náà jẹ́ Olúwa lọ pẹ̀wa. ó tilẹ̀ jẹ́ , ènìyàn ọlọ́rùn líle ni wọn, dárí búburú àti ̀ṣẹ̀ wa , o gbà gẹ́gẹ́ ìní rẹ."

10 Nígbà náà ni Olúwa , "Èmi májẹ̀kan pẹ̀yín. Níwájú gbogbo ènìyàn rẹ Èmi yóò ṣe ìyanu, a ì ṣe orílẹ̀-èdè gbogbo ayé . Àwọn ènìyàn ìwọ ń gbé láàrín wọn yóò i iṣẹ́ Èmi Olúwa yóò ṣe fún ti ̀. 11 Ṣe ohun Èmi pàṣẹ fún lónìí. Èmi àwọn ará Amori, àwọn ará Kenaani, àwọn ará Peresi, àwọn ará Hiti, àwọn ará Hifi àti àwọn ará Jebusi jáde níwájú rẹ. 12 Máa ṣọ́ra o ba à àwọn ti ó n gbé ilẹ̀ náà ìwọ ń lọ májẹ̀, nítorí wọn yóò jẹ́ ìdẹwò láàrín rẹ. 13 pẹpẹ wọn lulẹ̀, fọ́ òkúta mímọ́ wọn, o òpó Aṣerah wọn. (Ère òrìṣà wọn.) 14 34.14: Ek 20.5; 34.7; De 4.24; 5.9.ṣe sin ọlọ́run mìíràn, nítorí Olúwa, orúkọ ẹni ti ń jẹ́ Òjòwú, Ọlọ́run owú ni.

15 "Máa ṣọ́ra ṣe àwọn ènìyàn ń gbé ilẹ̀ náà májẹ̀; nígbà wọ́n ń ṣe àgbèrè tọ òrìṣà wọn, wọ́n ẹbọ wọn, wọn yóò yín, ̀yin yóò jẹ ẹbọ wọn. 16 Nígbà ìwọ yàn nínú àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin rẹ ìyàwó, àwọn ọmọbìnrin wọ̀nyí yóò ṣe àgbèrè tọ òrìṣà wọn, wọn yóò àwọn ọmọkùnrin yín náà ṣe bẹ́̀ gẹ́gẹ́.

17 34.17: Ek 20.4. "Ìwọ gbọdọ̀ ère òrìṣàkórìṣà fún ara rẹ.

18 34.18: Ek 12.15-20. "Àjọ àkàrà àìwú ni ìwọ máa pamọ́. Fún ọjọ́ méje ni ìwọ yóò jẹ àkàrà aláìwú, gẹ́gẹ́ Èmi ti pa á láṣẹ fún . Ṣe èyí ìgbà a yàn nínú oṣù Abibu, nítorí oṣù náà ni jáde láti Ejibiti .

19 34.19-20: Ek 13.2,11-16. "Gbogbo àkọ́inú kọ̀̀kan tèmi i ṣe, pẹ̀àkọ́gbogbo ohun ̀sìn rẹ, bóyá ti màlúù tàbí ti àgùntàn. 20 Àkọ́kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ni ìwọ ó fi ̀dọ́-àgùntàn padà, ṣùgbọ́n ìwọ á padà, ọrùn rẹ̀. Ra gbogbo àkọ́ọkùnrin rẹ padà.

"Ẹnikẹ́ni gbọdọ̀ síwájú mi ọwọ́ òfo.

21 34.21: Ek 20.8-10; 23.12; 31.12-17; 35.2; De 5.12-15. "Ọjọ́ mẹ́ni ìwọ yóò ṣiṣẹ́, ṣùgbọ́n ọjọ́ keje ìwọ yóò sinmi; kódà àkókò ìfúnrúgbìn àti àkókò ìkórè ìwọ gbọdọ̀ sinmi.

22 34.22-24: Ek 23.14-17; Le 23.1-44; De 16.1-17. "Ṣe àjọ ̀sẹ̀ pẹ̀àkọ́so èso alikama àti àjọ ìkórè òpin ọdún. 23 ̀̀mẹ́ta lọ́dún, gbogbo àwọn ọkùnrin ni ó farahàn níwájú Olúwa Olódùmarè, Ọlọ́run Israẹli. 24 Èmi yóò orílẹ̀-èdè jáde níwájú rẹ, Èmi yóò ìpín rẹ fẹ̀, ẹnikẹ́ni yóò gba ilẹ̀ rẹ nígbà ìwọ gòkè lọ ìgbà mẹ́ta lọ́dún kọ̀̀kan láti farahàn níwájú Olúwa Ọlọ́run rẹ.

25 34.25: Ek 23.18; Le 2.11; Ek 12.10. "ṣe ta ̀jẹ̀ ẹbọ mi pẹ̀ohunkóhun ó ìwúkàrà, o ṣe jẹ́ ẹbọ ìrékọjá títí di òwúrọ̀.

26 34.26: Ek 23.19; De 14.21; 26.2-11. "àkọ́èso ilẹ̀ rẹ ó dára jùlọ ilé Olúwa Ọlọ́run rẹ.

"Ìwọ gbọdọ̀ bọ ọmọ ewúrẹ́ nínú omi ọmú ìyá rẹ̀."

27 Olúwa fún Mose , "Kọ àwọn ̀rọ̀ wọ̀nyí sílẹ̀, nítorí nípa àwọn ̀rọ̀ wọ̀nyí ni Èmi ìwọ àti Israẹli májẹ̀." 28 Mose níbẹ̀ pẹ̀Olúwa fún ogójì ̀sán àti ogójì òru láìjẹ oúnjẹ tàbí mu omi. Ó kọ ̀rọ̀ májẹ̀náà òfin mẹ́wàá sára wàláà.

Dídán ojú Mose

29 34.29-35: 2Kọ 3.7-16. Nígbà Mose sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè Sinai pẹ̀wàláà ̀méjì ọwọ́ rẹ̀, òun mọ̀ ojú òun ń dán nítorí ó Olúwa sọ̀rọ̀. 30 Nígbà Aaroni àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli Mose, ojú rẹ̀ ń dán, ̀ń wọ́n láti súnmọ́ ọn. 31 Ṣùgbọ́n Mose wọn; Aaroni àti gbogbo àwọn olórí àjọ padà a, ó wọn sọ̀rọ̀. 32 Lẹ́yìn èyí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli súnmọ́ ọn, ó fún wọn gbogbo àṣẹ Olúwa fún un lórí òkè Sinai.

33 Nígbà Mose parí ̀rọ̀ sísọ fún wọn. Ó fi ìbòjú bo ojú rẹ̀. 34 Ṣùgbọ́n nígbàkígbà Mose níwájú Olúwa láti a sọ̀rọ̀, á ṣí ìbòjú náà títí yóò fi jáde. Nígbà ó jáde, á sọ fún àwọn ọmọ Israẹli ohun a ti pàṣẹ fún un, 35 àwọn ọmọ Israẹli i ojú rẹ̀ ń dán. Mose á tún fi ìbòjú bo ojú rẹ̀ títí á fi lọ Olúwa sọ̀rọ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-