Publicidade

Êxodo 6

1 Nígbà náà Olúwa sọ fún Mose , "ìsin yìí, ìwọ yóò ohun èmi yóò ṣe Farao pẹ̀ọwọ́ agbára ńlá mi ni yóò fi jẹ́ wọn lọ; pẹ̀ọwọ́ agbára ńlá mi, òun yóò wọn jáde kúrò orílẹ̀-èdè rẹ̀."

2 Ọlọ́run tún sọ fún Mose , "Èmi ni Olúwa. 3 Mo fi ara hàn Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu Ọlọ́run alágbára, ṣùgbọ́n nípa orúkọ mi Olúwa, Èmi fi ara mi hàn wọ́n. 4 Èmí tún fi ìdí májẹ̀mi múlẹ̀ pẹ̀wọn láti fún wọn ilẹ̀ Kenaani, ilẹ̀ wọn gbé gẹ́gẹ́ àjèjì. 5 Èmi ti tún gbọ́ kíkùn àwọn ọmọ Israẹli àwọn àwọn ará Ejibiti gẹ́gẹ́ ẹrú, àti èmi ti rántí májẹ̀mi.

6 "Sọ fún àwọn ará ilé Israẹli, Èmi ni Olúwa, Èmi yóò sọ yín di òmìnira kúrò nínú àjàgà àwọn ará Ejibiti. Èmi yóò gbà yín sílẹ̀ kúrò oko ẹrú wọn. Èmi yóò a yín sílẹ̀ pẹ̀apá nínà (àwọn iṣẹ́ ìyanu) àti pẹ̀ìdájọ́ ńlá. 7 Èmi yóò un yín ènìyàn mi, èmi yóò jẹ́ Ọlọ́run yín. Nígbà náà ni ̀yin yóò mọ̀ , èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, ẹni ó un yín jáde kúrò nínú àjàgà àwọn ará Ejibiti. 8 Èmi yóò un yín ilẹ̀ náà ti èmi ti búra pẹ̀ìgbọ́wọ́sókè láti fi fún Abrahamu. Isaaki àti Jakọbu. Èmi yóò fi fún un yín ohun ìní, Èmi ni Olúwa.’ "

9 Mose sọ èyí fún àwọn ará Israẹli, ṣùgbọ́n wọn fi etí sílẹ̀ Mose nítorí ọkàn wọn rẹ̀wẹ̀àti nítorí ìgbèkùn búburú ohun ó ti kọ́ sọ wọn oko ẹrú wọn.

10 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose. 11 "Lọ, sọ fún Farao ọba Ejibiti ó jẹ́ àwọn ará Israẹli lọ kúrò orílẹ̀-èdè rẹ̀."

12 Ṣùgbọ́n Mose sọ fún Olúwa , "Nígbà ti àwọn ará Israẹli jẹ́ ènìyàn mi fetí ̀rọ̀ mi, báwo ni Farao yóò ṣe fetí ̀rọ̀ mi, nígbà ti mo jẹ́ akólòlò?"

Àkọsílẹ̀ ìdílé Mose Àti Aaroni

13 Olúwa ìran Mose àti Aaroni sọ̀rọ̀ nípa àwọn ará Israẹli àti Farao ọba Ejibiti, ó pàṣẹ fún wọn wọn àwọn Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti.

14 Wọ̀nyí ni olórí ìran wọn:

àwọn ọmọ Reubeni àkọ́Israẹli ni:

Hanoku, Pallu, Hesroni àti Karmi.

Àwọn wọ̀nyí ni ìdílé Reubeni.

15 Àwọn ọmọ Simeoni ni:

Jemueli, Jamini, Ohadi, Jakini, Sohari àti Saulu ọmọ obìnrin Kenaani.

Àwọn wọ̀nyí ni ìran Simeoni.

16 Ìwọ̀nyí ni orúkọ àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ àkọsílẹ̀ wọn:

Gerṣoni, Kohati àti Merari.

Lefi lo ̀tàdínlógóje (137) ọdún láyé.

17 Àwọn ọmọ Gerṣoni ni ìran wọn ni:

Libni àti Ṣimei.

18 Àwọn ọmọ Kohati ni:

Amramu, Isari, Hebroni àti Usieli.

Kohati lo ̀tàléláádóje (133) ọdún láyé.

19 Àwọn ọmọ Merari ni:

Mahili àti Muṣi.

Ìwọ̀nyí ni ìran Lefi gẹ́gẹ́ àkọsílẹ̀ wọn.

20 Amramu fẹ́ Jokebedi arábìnrin baba rẹ̀ ìyàwó. Jokebedi Aaroni àti Mose fún un.

Amramu lo ̀tàdínlógóje (137) ọdún láyé.

21 Àwọn ọmọ Isari ni:

Kora, Nefegi àti Sikri.

22 Àwọn ọmọ Usieli ni:

Miṣaeli, Elsafani àti Sitiri.

23 Aaroni fẹ́ Eliṣeba ọmọbìnrin Amminadabu í ṣe arábìnrin Nahiṣoni, ó Nadabu, Abihu, Eleasari àti Itamari.

24 Àwọn ọmọ Kora ni:

Asiri, Elkana àti Abiasafu.

Ìwọ̀nyí ni ìran Kora.

25 Eleasari ọmọ Aaroni fẹ́ ̀kan lára àwọn ọmọbìnrin Putieli ìyàwó, ó Finehasi fún un.

Ìwọ̀nyí ni olórí àwọn Lefi ni ìdílé ìdílé.

26 Aaroni àti Mose yìí kan náà ni Olúwa sọ fún , "àwọn ará Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti ìsọ̀ìsọ̀." 27 Àwọn ni ó Farao ọba Ejibiti sọ̀rọ̀ nípa kíkó àwọn ará Israẹli jáde kúrò ni Ejibiti, àní Mose àti Aaroni yìí kan náà ni.

Aaroni di agbẹnusọ fún Mose

28 Nígbà Olúwa Mose sọ̀rọ̀ ni Ejibiti, 29 Olúwa sọ fún Mose , "Èmi ni Olúwa. Sọ ohun gbogbo ti mo ti sọ fún fún Farao ọba Ejibiti."

30 Ṣùgbọ́n Mose iwájú Olúwa , "Níwọ́n ìgbà ti mo jẹ́ akólòlò, ̀ti Farao yóò ṣe fi etí mi?"

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-