Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 11

Ilé ìṣọ́ Babeli

1 Lẹ́yìn náà, gbogbo àgbáyé ń sọ èdè kan ṣoṣo. 2 àwọn ènìyàn ṣe ń tẹ̀síwájú lọ ìhà ìlà-oòrùn, wọ́n pẹ̀tẹ́lẹ̀ kan ilẹ̀ Ṣinari,11.2 tí ó túmọ̀ sí, Babeli wọ́n tẹ̀síbẹ̀.

3 Wọ́n fún ara wọn , ", jẹ́ a mọ bíríkì a sún wọ́n jìnà." Bíríkì ni wọ́n ń ipò òkúta, àti ̀ilẹ̀ wọn ń láti wọn papọ̀ dípò ẹfun (òkúta láìmù wọ́n fi ń ṣe símẹ́ńtì àti omi). 4 Nígbà náà ni wọ́n , ", jẹ́ a tẹ ìlú kan fún ara wa, a kọ́ ilé ìṣọ́ kan yóò kan ̀run, a ba à orúkọ,11.4 tí ó túmọ̀ sí, òkìkí a káàkiri sórí gbogbo ilẹ̀ ayé."

5 Ṣùgbọ́n, Olúwa sọ̀kalẹ̀ láti wo ìlú àti ilé ìṣọ́ àwọn ènìyàn náà ń kọ́. 6 Olúwa , "àwọn ènìyàn ń jẹ́ ̀kan àti èdè kan wọ́n bẹ̀rẹ̀ í ṣe iṣẹ́ yìí, ohun wọ́n gbèrò wọn le ṣe yọrí. 7 , jẹ́ a sọ̀kalẹ̀ lọ, a da èdè wọn èdè wọn ba à ara wọn mọ́."

8 Olúwa wọn sórí ilẹ̀ gbogbo, wọ́n ṣíwọ́ ìlú náà wọn ń tẹ̀. 9 Ìdí èyí ni a fi é Babeli11.9 Èyí ní Babiloni; Babeli ni èdé Heberu tí a mọ̀ sí ìdàrúdàpọ̀. nítorí ibẹ̀ ni Olúwa ti da èdè gbogbo ayé . Olúwa àwọn ènìyàn gbogbo orí ilẹ̀ ayé.

Ìran Ṣemu fi ti Abramu

10 Wọ̀nyí ni ìran Ṣemu.

Ọdún méjì lẹ́yìn ìkún omi, Ṣemu ọgọ́rùn-ún ọdún ni ó Arfakṣadi. 11 Lẹ́yìn ó Arfakṣadi, Ṣemu tún láààyè fún ̀́dẹ́gbẹ̀ta ọdún (500), ó àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin mìíràn.

12 Nígbà Arfakṣadi ọdún márùndínlógójì ni ó Ṣela. 13 Arfakṣadi láààyè fún ọdún mẹ́tàlénírinwó (403) lẹ́yìn ó Ṣela, ó àwọn ọmọbìnrin àti àwọn ọmọkùnrin mìíràn.

14 Nígbà Ṣela ọmọ ọgbọ̀n ọdún ni ó Eberi. 15 Ṣela láààyè fún ọdún mẹ́tàlénírinwó (403) lẹ́yìn ó Eberi tán, ó àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin mìíràn.

16 Eberi jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n, ó Pelegi. 17 Eberi láààyè fún irinwó ọdún ó ọgbọ̀n (430) lẹ́yìn ó Pelegi, ó àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin mìíràn.

18 Nígbà Pelegi ọmọ ọgbọ̀n ọdún ni ó Reu. 19 Pelegi tún láààyè fún igba ọdún ó mẹ́sàn-án (209) lẹ́yìn ó Reu, ó àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin mìíràn.

20 Nígbà Reu ọdún méjìlélọ́gbọ̀n ni ó Serugu. 21 Reu tún láààyè lẹ́yìn ó Serugu fún igba ọdún ó méje (207), ó àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin mìíràn.

22 Nígbà Serugu ọmọ ọgbọ̀n ọdún ni ó Nahori. 23 Serugu láààyè fún igba ọdún lẹ́yìn ó Nahori, ó àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin mìíràn.

24 Nígbà Nahori ọmọ ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ̀n, ó Tẹra. 25 Nahori láààyè fún ọdún mọ́kàn dín lọ́gọ́lẹ́yìn ìbí Tẹra, ó àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin mìíràn.

26 Lẹ́yìn Tẹra ọmọ àádọ́rin ọdún ó Abramu, Nahori àti Harani.

Ìgbé ayé Abrahamu

27 Wọ̀nyí ni ìran Tẹra.

Tẹra ni baba Abramu, Nahori àti Harani. Harani Lọti. 28 Harani ṣáájú Tẹra baba rẹ̀ ilẹ̀ ìbí rẹ̀ Uri ti ilẹ̀ Kaldea. 29 Abramu àti Nahori gbéyàwó. Orúkọ aya Abramu ni Sarai, nígbà aya Nahori ń jẹ́ Milka, ṣe ọmọ Harani. Harani ni ó Milka àti Iska. 30 Sarai yàgàn, bímọ.

31 Tẹra ọmọ rẹ̀ Abramu àti Lọti ọmọ Harani, ọmọ ọmọ rẹ̀, ó Sarai i ṣe aya ọmọ rẹ̀. Abramu pẹ̀gbogbo wọn jáde kúrò Uri ti Kaldea láti lọ ilẹ̀ Kenaani. Ṣùgbọ́n nígbà wọn Harani wọ́n tẹ̀síbẹ̀.

32 Nígbà Tẹra ọmọ igba ọdún ó márùn-ún (205) ni ó Harani.

Veja também