Publicidade

Gênesis 14

Abramu gba Lọti

1 àsìkò yìí ni Amrafeli ọba Ṣinari, Arioku ọba Ellasari, Kedorlaomeri ọba Elamu àti Tidali ọba Goyimu 2 jáde lọ láti Bera ọba Sodomu, Birṣa ọba Gomorra, Ṣenabu ọba Adma, Ṣemeberi ọba Seboimu àti ọba Bela (èyí ni Soari) jagun. 3 Gbogbo àwọn ọba wọ̀nyí ni ó ogun wọn jọ pọ̀ àfonífojì Siddimu (ti o túmọ̀ Òkun Iyọ̀). 4 Fún ọdún méjìlá gbáko ni wọ́n ti ń sin Kedorlaomeri ẹrú. Ṣùgbọ́n nígbà ó di ọdún kẹtàlá wọ́n ṣọ̀tẹ̀ i.

5 ọdún kẹrìnlá, ni Kedorlaomeri àti àwọn ọba wọ́n ti jọ ni májẹ̀àṣepọ̀ , wọ́n ṣígun, wọ́n ṣẹ́gun ará Refaimu Aṣteroti-Karnaimu, àwọn ará Susimu ni Hamu, àwọn ará Emimu pẹ̀tẹ́lẹ̀ Kiriataimu, 6 àti àwọn ará Hori orí òkè wọ̀n-ọn-nì Seiri, títí ó fi Eli-Parani etí ijù. 7 Wọ́n tún yípadà lọ En-Miṣpati (ti o túmọ̀ Kadeṣi), wọ́n ṣẹ́gun gbogbo ilẹ̀ àwọn Amaleki, àti àwọn ará Amori ó tẹ̀Hasason Tamari pẹ̀.

8 Nígbà náà ni ọba Sodomu, ọba Gomorra, ọba Adma, ọba Seboimu àti ọba Bela (èyí ni Soari), àwọn ọmọ-ogun wọn, wọ́n pa ibùdó ogun wọn Àfonífojì Siddimu, 9 láti kojú ìjà Kedorlaomeri ọba Elamu, Tidali ọba Goyimu, Amrafeli ọba Ṣinari àti Arioku ọba Ellasari (ọba mẹ́rin kọjú ìjà ọba márùn-ún). 10 Àfonífojì Siddimu kún fún kòtò ̀ilẹ̀, nígbà ọba Sodomu àti ọba Gomorra , díẹ̀ nínú àwọn ọkùnrin ogun náà ṣubú sínú àwọn kòtò náà, àwọn tókù sálọ orí òkè. 11 Àwọn ọba mẹ́rẹ̀̀rin náà gbogbo ẹrù Sodomu àti Gomorra àti oúnjẹ wọn; wọ́n lọ. 12 Wọ́n Lọti ọmọ arákùnrin Abramu ń gbé Sodomu àti gbogbo ohun ìní rẹ̀.

13 Ẹnìkan ó àsálà ròyìn fún Abramu, ará Heberu ni. Abramu ti tẹ̀̀gbẹ́ igi ńlá igbó Mamre ará Amori, arákùnrin Eṣkolu àti Aneri: àwọn ẹni ó ń Abramu àṣepọ̀. 14 Nígbà Abramu gbọ́ , a di Lọti ìgbèkùn, ó àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ a ilẹ̀ rẹ̀ ó ti kọ́ ni ogun jíjà jáde, wọ́n jẹ́ okòó lọ́̀dúnrún ó dín méjì (318) ènìyàn, ó lépa wọn títí Dani. 15 ̀gànjọ́ òru, Abramu pín àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ méjì, ó kọlù wọ́n, ó ṣẹ́gun wọn, ó wọn títí Hoba ó apá òsì Damasku. 16 Gbogbo ìkógun ni ó gbà padà àti ọmọ arákùnrin rẹ̀, Lọti pẹ̀ohun ìní rẹ̀, àti àwọn obìnrin pẹ̀àwọn ènìyàn tókù.

17 14.17-20: Hb 7.1-10. Nígbà Abramu ti ṣẹ́gun Kedorlaomeri àti àwọn ọba ó pẹ̀rẹ̀, ọba Sodomu lọ pàdé rẹ̀ àfonífojì Ṣafe (èyí ni àfonífojì Ọba).

18 Melkisedeki ọba Salẹmu14.18 tí ó túmọ̀ sí, Jerusalẹmu oúnjẹ àti ọtí wáìnì jáde . Òun ni àlùfáà Ọlọ́run ̀gá-ògo. 19 Ó súre fún Abramu, ,

"Ìbùkún ni fún Abramu ti Ọlọ́run ̀gá-ògo,

Ẹni ó ̀run òun ayé.

20 Ìbùkún ni fún Ọlọ́run ̀gá-ògo jùlọ,

ó fi àwọn ̀rẹ lọ́wọ́."

Abramu fún un ìdámẹ́wàá ohun gbogbo.

21 Ọba Sodomu fún Abramu , "àwọn ènìyàn mi fún mi, ṣùgbọ́n àwọn ẹrù fún ara rẹ."

22 Ṣùgbọ́n Abramu ọba Sodomu lóhùn , "Mo ti búra fún Olúwa, Ọlọ́run ̀gá-ògo, ó ̀run àti ayé, mo ti gbọ́wọ́ sókè, 23 , èmi yóò láti fọ́nrán òwú títí okùn bàtà, àti , èmi yóò ohun kan ṣe tìrẹ, ìwọ ó ba à , Mo sọ Abramu di ọlọ́rọ̀.’ 24 Èmi yóò gba ohunkóhun yàtọ̀ ohun àwọn ọkùnrin mi ti jẹ́, ṣùgbọ́n fi ìpín fún àwọn ọkùnrin ó mi lọ, Aneri, Eṣkolu àti Mamre. Jẹ́ wọn ó gba ìpín wọn."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-