Pular para o conteúdo
Publicidade

Gênesis 18

23 Nígbà náà ni Abrahamu súnmọ́ ̀dọ̀ Olúwa, ó , "Ìwọ yóò ha pa olódodo ènìyàn àti ènìyàn búburú run papọ̀ ?" 24 "ó ṣe ìwọ àádọ́ta olódodo nínú ìlú náà, ìwọ yóò ha run ún, ìwọ yóò ha ìlú náà nítorí àwọn àádọ́ta olódodo ó nínú rẹ̀ náà? 25 jẹ́ bẹ́̀! Dájúdájú ìwọ yóò ṣe ohun ó jọ bẹ́̀, láti pa olódodo pẹ̀àwọn ènìyàn rere àti àwọn ènìyàn búburú. Dájúdájú, ìwọ yóò ṣe èyí ó tọ́ bi?"

26 Olúwa , "mo àádọ́ta olódodo ìlú Sodomu, èmi yóò ìlú náà nítorí tiwọn."

27 Abrahamu tún tẹ̀síwájú , "ó nísinsin yìí, níwọ̀n èmi ti ìgboyà láti bẹ̀rẹ̀ sọ̀rọ̀ níwájú Olúwa, èmi ẹni í ṣe erùpẹ̀ àti eérú, 28 ó ṣe pe olódodo márùndínláàádọ́ta ni ó nínú ìlú, ìwọ yóò ha pa ìlú náà run nítorí ènìyàn márùn-ún ?"

Olúwa dáhùn , "Èmi yóò pa ìlú náà run mo olódodo márùndínláàádọ́ta nínú rẹ̀."

29 Òun tún lẹ́̀kan si , "ó ṣe ogójì ni ń kọ́?"

Olúwa tún , "Èmi yóò pa ìlú náà run mo olódodo ogójì nínú rẹ̀."

30 Abrahamu tún bẹ Olúwa , "Olúwa ṣe bínú, ṣùgbọ́n èmi yóò sọ̀rọ̀. ó ṣe ọgbọ̀n ni a níbẹ̀ ń kọ́?"

Olúwa dáhùn , "ọgbọ̀n, èmi yóò pa ìlú run."

31 Abrahamu , "Níwọ́n mo ti ìgboyà láti Olúwa sọ̀rọ̀ báyìí, jẹ́ n tẹ̀síwájú. o ṣe olódodo ogún péré ni ó nínú ìlú náà ń kọ́?"

Olúwa dáhùn , "Èmi yóò pa á run nítorí ogún ènìyàn náà."

32 Abrahamu , "Jọ̀wọ́ ṣe bínú Olúwa. Jẹ́ ń béèrè lẹ́̀kan si. ó ṣe ènìyàn mẹ́wàá ni ó jẹ́ olódodo ń kọ́?"

Olúwa , "Nítorí ènìyàn mẹ́wàá náà, èmi yóò pa á run."

33 Olúwa tirẹ̀ lọ, nígbà ó Abrahamu sọ̀rọ̀ tán, Abrahamu padà sílé.

Veja também