Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 2

18 Olúwa Ọlọ́run , "dára ọkùnrin òun nìkan. Èmi yóò ṣe olùrànlọ́wọ́ ó i rẹ̀ fún un."

19 Lẹ́yìn Olúwa Ọlọ́run ti àwọn ẹranko inú igbó àti gbogbo ẹyẹ ojú ̀run láti inú erùpẹ̀ ilẹ̀. Ó wọn tọ ọkùnrin náà láti wo orúkọ yóò sọ wọ́n; orúkọ ó sọ gbogbo ̀alààyè náà ni wọ́n ń jẹ́. 20 Gbogbo ohun ̀sìn, ẹyẹ ojú ̀run àti gbogbo ẹranko igbó ni ọkùnrin náà sọ orúkọ.

Ṣùgbọ́n fún Adamu ni a olùrànlọ́wọ́ ó i rẹ̀. 21 Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run ọkùnrin náà sùn fọnfọn; nígbà ó ń sùn, Ọlọ́run yọ egungun ìhà rẹ̀ kan, ó fi ẹran-ara ó padà. 22 Olúwa Ọlọ́run obìnrin láti inú egungun ó yọ ìhà ọkùnrin náà, Ó mu obìnrin náà tọ̀ ́ .

23 Ọkùnrin náà ,

"Èyí ni egungun láti inú egungun mi

àti ẹran-ara nínú ẹran-ara mi;

obìnrinni a ó máa é,

nítorí a un jáde láti ara ọkùnrin."

24 2.24: Mt 19.5; Mk 10.7; 1Kọ 6.16; Ef 5.31. Nítorí ìdí èyí, ọkùnrin yóò fi baba àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀, yóò dàpọ̀ mọ́ aya rẹ̀, wọn yóò di ara kan.

Veja também