Publicidade

Gênesis 21

Ìbí Isaaki

1 Olúwa bẹ Sara ó ti , Olúwa ṣe fún Sara gẹ́gẹ́ ó ti ṣèlérí. 2 Sara lóyún, ó ọmọkùnrin kan fún Abrahamu ọjọ́ ogbó rẹ̀, àkókò náà gan an Ọlọ́run ti ṣèlérí fún un. 3 Abrahamu sọ orúkọ ọmọ náà Sara fun un Isaaki. 4 Nígbà Isaaki ọmọ ọjọ́ mẹ́jọ, Abrahamu kọ ́ ilà gẹ́gẹ́ Ọlọ́run ti pàṣẹ fún un. 5 Ẹni ọgọ́rùn-ún ọdún ni Abrahamu nígbà ó Isaaki.

6 Sara , "Ọlọ́run ti pa lẹ́rìn-ín. Gbogbo ẹni ó gbọ́ mo bímọ yóò rẹ́rìn-ín pẹ̀mi." 7 Ó fi kún un , "Ta ni ó le sọ fún Abrahamu , Sara yóò di ọlọ́mọ? Síbẹ̀síbẹ̀, mo tún ọmọ fún Abrahamu ìgbà ogbó rẹ."

A Hagari àti Iṣmaeli jáde

8 Nígbà ọmọ náà dàgbà, ó gbà á lẹ́nu ọmú, ọjọ́ a gba Isaaki lẹ́nu ọmú, Abrahamu ṣe àsè ńlá. 9 Ṣùgbọ́n Sara ọmọ Hagari ará Ejibiti ó fún Abrahamu ó fi ṣe ẹlẹ́, 10 ó fún Abrahamu , "ẹrúbìnrin yìí àti ọmọ rẹ̀ jáde, nítorí ọmọ ẹrú yìí ọmọ mi Isaaki pín ogún."

11 ̀rọ̀ náà ba Abrahamu lọ́kàn jẹ́ gidigidi nítorí ọmọ rẹ̀ náà à ni Iṣmaeli i ṣe. 12 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run fun Abrahamu , "ṣe ba ọkàn jẹ́ nítorí ọmọ náà àti ẹrúbìnrin rẹ. Gbọ́ ohun Sara fún , nítorí nínú Isaaki ni a ó ti pe irú-ọmọ rẹ̀. 13 Èmi yóò sọ ọmọ ẹrúbìnrin náà di orílẹ̀-èdè pẹ̀, nítorí ọmọ rẹ ni."

14 Abrahamu dìde kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ó oúnjẹ àti ìgò omi kan, ó wọn fún Hagari, ó wọn e léjìká, ó e jáde pẹ̀ọmọ náà. Ó lọ lọ́rẹ, ó ń ṣe alárìnkiri ijù Beerṣeba.

15 Nígbà omi inú ìgò náà tan, ó gbé ọmọ náà abẹ́ igbó. 16 Ó lọ, ó jókòó nítòsí ibẹ̀, níwọ̀n ìtafà kan, nítorí, ó ó nínú ara rẹ̀ , "Èmi fẹ́ wo ọmọ náà yóò ṣe ." ó ti jókòó tòsí ibẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ sọkún.

17 Ọlọ́run gbọ́ ohun ẹkún náà, Angẹli Ọlọ́run pe Hagari láti ̀run, ó fun un , "Hagari, kín ni ó ṣe ́? bẹ̀nítorí Ọlọ́run ti gbọ́ ẹkún ọmọ náà níbi o tẹ́ . 18 Dìde, gbé ọmọ náà sókè, o dìímú (ú nínú) nítorí èmi yóò sọ ọmọ náà di orílẹ̀-èdè ńlá."

19 Ọlọ́run ṣí ojú Hagari, ó kànga kan, ó lọ síbẹ̀, ó rọ omi kún inú ìgò náà, ó fún ọmọ náà mu.

20 Ọlọ́run pẹ̀ọmọ náà ó ti ń dàgbà, ó ń gbé nínú ijù, ó di tafàtafà. 21 Nígbà ó ń gbé ni aginjù Parani, ìyá rẹ̀ fẹ́ ìyàwó fún un láti ilẹ̀ Ejibiti .

Májẹ̀Beerṣeba

22 àkókò yìí ni ọba Abimeleki àti Fikoli, olórí ogun rẹ̀ fún Abrahamu , "Ọlọ́run pẹ̀rẹ̀ nínú gbogbo ohun ó ń ṣe. 23 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, fi Ọlọ́run búra fún mi, ìwọ yóò tàn àti àwọn ọmọ mi àti àwọn ìran mi, ìwọ yóò fi inú rere hàn fún mi àti orílẹ̀-èdè ìwọ ti ṣe àtìpó, mo ti fihàn fún pẹ̀."

24 Abrahamu , "Èmí búra."

25 Nígbà náà ni Abrahamu fi ̀dùn ọkàn rẹ̀ hàn fún Abimeleki nípa kànga àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ gbà lọ́wọ́ rẹ̀. 26 Ṣùgbọ́n Abimeleki dáhùn , "Èmi mọ ẹni ó ṣe nǹkan yìí. Ìwọ sọ fún mi, bẹ́̀ ni èmi gbọ́, ṣe lónìí."

27 Abrahamu àgùntàn àti màlúù , ó wọn fún Abimeleki. Àwọn méjèèjì májẹ̀. 28 Abrahamu ya abo ̀dọ́-àgùntàn méje nínú agbo àgùntàn rẹ̀ sọ́tọ̀. 29 Abimeleki béèrè lọ́wọ́ Abrahamu , "Kín ni ìtumọ̀ yíyà ìwọ ya àwọn ̀dọ́-àgùntàn méje wọ̀nyí sọ́tọ̀ ."

30 Ó dalóhùn , "Gba àwọn abo ̀dọ́-àgùntàn méje wọ̀nyí lọ́wọ́ mi gẹ́gẹ́ ̀èmi ni mo gbẹ́ kànga yìí."

31 Nítorí náà ni a ṣe ń pe ibẹ̀ náà ni Beerṣeba nítorí níbẹ̀ ni àwọn méjèèjì gbé búra.

32 Lẹ́yìn májẹ̀wọ́n Beerṣeba yìí, ni Abimeleki àti Fikoli olórí ogun rẹ̀ padà ilẹ̀ àwọn ará Filistini. 33 Abrahamu lọ́ igi tamariski kan Beerṣeba, níbẹ̀ ni ó pe orúkọ Olúwa Ọlọ́run ayérayé. 34 Abrahamu gbé ilẹ̀ àwọn ará Filistini fún ọjọ́ pípẹ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-