Publicidade

Gênesis 25

Ikú Abrahamu

1 Abrahamu tún fẹ́ aya mìíràn, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ketura. 2 Ó Simrani, Jokṣani, Medani, Midiani, Iṣbaki, àti Ṣua 3 Jokṣani ni baba Ṣeba àti Dedani, àwọn ìran Dedani ni àwọn ara Asṣuri, Letusi àti Leumiti. 4 Àwọn ọmọ Midiani ni Efani, Eferi, Hanoku, Abida àti Eldaa. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ìran Ketura.

5 Abrahamu fi ohun gbogbo ó fún Isaaki. 6 Ṣùgbọ́n Abrahamu , Abrahamu fún àwọn ọmọ àwọn àlè rẹ̀ fún un ̀bùn, ó wọn jáde lọ fún Isaaki ọmọ rẹ ilẹ̀ ìlà-oòrùn.

7 Gbogbo àpapọ̀ ọdún Abrahamu láyé jẹ́ igba kan ó dín mẹ́̀́dọ́gbọ̀n (175). 8 Abrahamu ọjọ́ ogbó rẹ̀. Ó dàgbà, ó darúgbó ó . A sin ín ibojì àwọn ènìyàn rẹ̀. 9 Àwọn ọmọ rẹ̀, Isaaki àti Iṣmaeli sin ín sínú ihò àpáta ni Makpela ̀gbẹ́ Mamre, oko Efroni ọmọ Sohari ará Hiti, 10 inú oko Abrahamu lọ́wọ́ ara Hiti yìí ni a sin Abrahamu àti Sara aya rẹ̀ . 11 Lẹ́yìn ikú Abrahamu, Ọlọ́run bùkún fún Isaaki ọmọ rẹ̀, ó ń gbé nítòsí kànga Lahai-Roi ìgbà náà.

Àwọn ìran Iṣmaeli

12 Wọ̀nyí ni ìran Iṣmaeli, ọmọ Abrahamu ẹni Hagari ará Ejibiti, ọmọ ̀dọ̀ Sara fún un.

13 Wọ̀nyí ni orúkọ àwọn ọmọ Iṣmaeli a ṣe wọn, bẹ̀rẹ̀ láti orí:

Nebaioti àkọ́,

Kedari, Adbeeli, Mibsamu,

14 Miṣima, Duma, Massa,

15 Hadadi, Tema, Jeturi,

Nafiṣi, àti Kedema.

16 Wọ̀nyí ni orúkọ àwọn ọmọ Iṣmaeli, wọ̀nyí ni orúkọ àwọn ọba méjìlá gẹ́gẹ́ ̀wọn.

17 Àpapọ̀ ọdún Iṣmaeli láyé jẹ́ ̀tàdínlógóje (137) ọdún, a sin ín pẹ̀àwọn ènìyàn rẹ̀. 18 Àwọn ìran rẹ̀ tẹ̀agbègbè Hafila títí ó fi Ṣuri, ̀ààlà Ejibiti, ìwọ ti ń lọ ìhà Asiria. Ó níwájú àwọn arákùnrin rẹ̀ gbogbo.

Jakọbu àti Esau

19 Wọ̀nyí ni ìtàn ìran Isaaki ọmọ Abrahamu.

Abrahamu Isaaki. 20 Nígbà Isaaki di ọmọ ogójì ọdún ni ó gbé Rebeka ọmọ Betueli ará Aramu ti Padani-Aramu í ṣe arábìnrin Labani ará Aramu ìyàwó.

21 Isaaki gbàdúrà Olúwa, nítorí aya rẹ̀ ó yàgàn, Olúwa gbọ́ àdúrà rẹ̀, Rebeka lóyún. 22 Àwọn ọmọ náà ń gbún ara wọn nínú rẹ̀, ó , "Èéṣe èyí ń ṣẹlẹ̀ mi," ó lọ béèrè lọ́dọ̀ Olúwa.

23 Olúwa fún un ,

"Orílẹ̀-èdè méjì ni ń bẹ nínú rẹ,

irú ènìyàn méjì ni yóò láti inú rẹ;

àwọn ènìyàn kan yóò jẹ́ alágbára ju èkejì lọ,

̀gbọ́n ni yóò máa sin àbúrò."

24 Nígbà ó àkókò fún un láti bímọ, ìbejì ni ó nínú rẹ̀, ọkùnrin ni wọ́n. 25 Èyí ó kọ jáde jẹ́ ọmọ pupa, irun bo gbogbo ara rẹ̀ aṣọ onírun, nítorí náà, wọ́n é Esau. 26 Lẹ́yìn èyí ni arákùnrin èkejì jáde , ọwọ́ rẹ̀ di Esau ni gìgísẹ̀ , nítorí náà ni wọn ṣe pe orúkọ rẹ ni Jakọbu. Ọmọ ọgọ́ta ọdún ni Isaaki, nígbà Rebeka wọn.

27 Àwọn ọmọkùnrin náà dàgbà. Esau di ọlọ́gbọ́n ọdẹ, ẹni ó fẹ́ràn àti máa dúró oko. Jakọbu jẹ́ ènìyàn jẹ́́jẹ́ ó ń gbé láàrín ìlú. 28 Isaaki, ẹni ó fẹ́ràn ẹran igbó fẹ́ràn Esau nítorí ẹran igbó Esau máa ń pa, ṣùgbọ́n Rebeka fẹ́ràn Jakọbu.

29 ọjọ́ kan, Jakọbu pa ìpẹ̀tẹ̀, Esau ti igbó ọdẹ , ó ti rẹ̀ ́. 30 Esau fún Jakọbu , "Èmí bẹ̀ , fi ìpẹ̀tẹ̀ rẹ pupa n bọ́ mi, nítorí ó rẹ̀ gidigidi." (Nítorí náà ni a ṣe ń pe orúkọ rẹ̀ Edomu.)

31 Jakọbu dáhùn , "burú, ṣùgbọ́n kọ́kọ́ ta ogún ìbí rẹ fún mi ."

32 Esau dáhùn , "ó mo ti fẹ́rẹ , àǹfààní kín ni ogún ìbí jẹ́ fún mi?"

33 Ṣùgbọ́n, Jakọbu dáhùn , "Kọ́kọ́ búra fún mi tèmi ni ogún ìbí náà yóò jẹ́." Báyìí ni Esau búra ó gbé ogún ìbí rẹ̀ fún Jakọbu.

34 Nígbà náà ni Jakọbu fi àkàrà àti ìpẹ̀tẹ̀ lẹntili fún Esau. Ó jẹ, ó mu, ó tirẹ̀ lọ.

Báyìí ni Esau gan ogún ìbí rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-