Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 3

17 3.17,18: Hb 6.8. Ọlọ́run fún Adamu , "Nítorí ìwọ fetí aya rẹ, ìwọ jẹ nínú èso igi mo pàṣẹ fún , Ìwọ gbọdọ̀ jẹ nínú rẹ̀,’

"Ègún ni fún ilẹ̀ nítorí rẹ;

nínú ̀pọ̀ làálàá ni ìwọ yóò jẹ nínú rẹ̀,

gbogbo ọjọ́ ayé rẹ.

18 Ilẹ̀ yóò hu ̀gún àti èṣùṣú fún ,

ewéko igbó ni ìwọ yóò máa jẹ.

19 Nínú òógùn ojú rẹ

ni ìwọ yóò máa jẹun

títí ìwọ yóò fi padà ilẹ̀,

nítorí inú ilẹ̀ ni a ti jáde ;

erùpẹ̀ ilẹ̀ à ni ìwọ,

ìwọ yóò padà di erùpẹ̀."

Veja também