Pular para o conteúdo
Publicidade

Gênesis 37

Àlá Josẹfu

1 Jakọbu gbé ilẹ̀ Kenaani ibi ti baba rẹ̀ ti gbé.

2 Èyí ni àwọn ìtàn Jakọbu.

Nígbà Josẹfu di ọmọ ọdún mẹ́tàdínlógún, ó ń ṣọ́ agbo ẹran pẹ̀àwọn arákùnrin rẹ̀, àwọn ọmọ Biliha àti Silipa aya baba rẹ̀ Josẹfu ń ròyìn àwọn aburú wọ́n ń ṣe fún baba wọn.

3 Israẹli fẹ́ràn Josẹfu ju gbogbo àwọn ọmọ rẹ̀ tókù lọ, nítorí ọjọ́ ogbó rẹ̀ ni ó i. O aṣọ aláràbarà ó kún fún onírúurú ọnà lára fún un. 4 Nígbà àwọn arákùnrin rẹ̀ i baba àwọn fẹ́ràn rẹ̀ ju gbogbo wọn lọ, wọ́n kórìíra rẹ̀, wọ́n ń fi ̀tanú a gbé, àlàáfíà láàrín wọn.

5 Josẹfu àlá kan, nígbà ó sọ fún àwọn arákùnrin rẹ̀, wọ́n túbọ̀ kórìíra rẹ̀ i. 6 O fún wọn , "fetí àlá mo , 7 à ó, àwa ń ìtí ọkà nínú oko, ó ṣe ìtí ọkà tèmi dìde dúró ṣánṣán, àwọn ìtí ọkà tiyín dúró ìtí tèmi , wọ́n ń foríbalẹ̀ fún un."

8 Àwọn arákùnrin rẹ̀ fún un , "Ìwọ ń gbèrò àti jẹ ọba wa lórí ? Tàbí ìwọ ó ṣe olórí wa nítòótọ́?" Wọn túbọ̀ kórìíra rẹ̀ i, nítorí àlá rẹ̀ àti nítorí ohun ó .

9 O tún àlá mìíràn, ó tún sọ ́ fún àwọn arákùnrin rẹ̀. Ó , tẹ́mi, "Mo tún àlá mìíràn, ó, oòrùn, òṣùpá àti ìràwọ̀ mọ́kànlá ń foríbalẹ̀ fún mi."

10 Nígbà ó sọ fún baba rẹ̀ àti àwọn arákùnrin rẹ̀ pẹ̀, baba rẹ̀ a , "Irú àlá wo ni ìwọ yìí? Ṣé ìyá rẹ, pẹ̀èmi àti àwọn ̀gbọ́n rẹ yóò foríbalẹ̀ níwájú rẹ ni?" 11 37.11,28: Ap 7.9.Àwọn arákùnrin rẹ̀ ń ṣe ìlara rẹ̀ ṣùgbọ́n baba rẹ̀ pa ̀rọ̀ náà mọ́ lọ́kàn rẹ̀.

Àwọn arákùnrin Josẹfu á

12 Àwọn arákùnrin rẹ̀ da ẹran baba wọn lọ Ṣekemu. 13 Israẹli fún Josẹfu , "Ṣé o mọ̀ , àwọn arákùnrin rẹ ń da ẹran Ṣekemu, , jẹ́ n rán wọn."

Josẹfu dáhùn , "Èmi nìyí."

14 O fún un , "Lọ àwọn arákùnrin rẹ àti àwọn agbo ẹran àlàáfíà, o jíṣẹ́ fún mi." Ó rán Josẹfu lọ láti àfonífojì Hebroni.

Nígbà Josẹfu Ṣekemu, 15 ọkùnrin kan i ó ń rìn kiri inú pápá, ó bi í , "Kín ni ò ń ?"

16 Ó dáhùn , "Àwọn arákùnrin mi ni ń , ǹjẹ́ o mọ ibi wọ́n pẹ̀agbo ẹran?"

17 Ọkùnrin náà dáhùn , "Wọ́n ti kúrò ìhín, mo gbọ́ wọ́n ń , jẹ́ a lọ Dotani.’ "

Josẹfu àwọn arákùnrin rẹ̀ lọ, ó wọn tòsí Dotani. 18 Ṣùgbọ́n wọ́n ti i ń bọ̀ lókèèrè, ó ̀dọ̀ wọn, wọn gbìmọ̀ pọ̀ láti pa á.

19 "Alálàá ni ń bọ̀ yìí," ni wọ́n ń fún ara wọn. 20 ", jẹ́ a pa á. a ju òkú rẹ̀ sínú kòtò, a ó , ẹranko búburú ni ó pa á, a máa wo ̀àlá rẹ̀ yóò gbà ṣẹ."

21 Nígbà Reubeni gbọ́ èyí, ó gbìyànjú láti gbà á sílẹ̀ ọwọ́ wọn, ó , "ṣe jẹ́ a gba ̀rẹ̀, 22 ṣe jẹ́ a ta ̀jẹ̀ sílẹ̀, ṣe fọwọ́ kàn án, kúkú ú sínú kòtò láààyè nínú aginjù níbí." Reubeni sọ èyí, ó ba à le gbà á kúrò lọ́wọ́ wọn, ó a padà lọ fún baba rẹ̀.

23 Nítorí náà, nígbà Josẹfu ̀dọ̀ àwọn arákùnrin rẹ̀, wọ́n bọ́ ̀rẹ̀—̀ọlọ́, aláràbarà ó wọ̀— 24 wọ́n un, wọ́n ú sínú kòtò. Kòtò náà ṣófo, omi nínú rẹ̀.

25 wọ́n ti jókòó láti jẹun, wọ́n gbójú sókè, wọ́n àwọn oníṣòwò ará Iṣmaeli wọ́n ń wọ́ bọ̀ láti Gileadi. Ìbákasẹ wọn ru tùràrí, ìkunra àti òjìá, wọ́n ń lọ Ejibiti.

26 Juda fún àwọn arákùnrin rẹ̀ , "Èrè ni ó jẹ́ a pa arákùnrin wa a bo ̀jẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀ ti ọkàn wa ń wa lẹ́bi? 27 , jẹ́ á á fún àwọn ará Iṣmaeli, àwa pa á, ṣè àbúrò wa ni, ẹran-ara wa àti ̀jẹ̀ wa i ṣe." Àwọn arákùnrin rẹ̀ fi ara mọ́ ohun ó sọ.

28 37.28: Ap 7.9. Nítorí náà, nígbà àwọn oníṣòwò ara Midiani ń kọjá, àwọn arákùnrin Josẹfu á jáde láti inú kòtò, wọ́n á fún àwọn ará Iṣmaeli ogún owó wúrà, wọ́n Josẹfu lọ ilẹ̀ Ejibiti.

29 Nígbà Reubeni padà ibi kòtò ó ri Josẹfu níbẹ̀ mọ́, ó fa aṣọ rẹ̀ ya pẹ̀ìbànújẹ́. 30 Ó padà lọ ̀dọ̀ àwọn arákùnrin rẹ̀, ó , "Ọmọdékùnrin náà níbẹ̀ mọ́! Níbo ni fẹ́ n wọ̀ báyìí?"

31 Nígbà náà ni wọ́n aṣọ Josẹfu, wọ́n pa ewúrẹ́ kan, wọ́n tẹ aṣọ náà bọ inú ̀jẹ̀ ewúrẹ́ náà. 32 Wọ́n aṣọ ọlọ́aláràbarà náà padà ̀dọ̀ baba wọn, wọ́n , "A èyí he nínú oko, yẹ̀ ́ , o mọ̀ bóyá ti ọmọ rẹ ni."

33 Ó a mọ̀, ó , "Háà! Aṣọ ọmọ mi ni, ẹranko búburú ti pa á jẹ, láìṣe àní àní, ó ti fa Josẹfu ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ."

34 Nígbà náà ni Jakọbu fa aṣọ rẹ̀ ya, ó wọ aṣọ ̀fọ̀, ó ṣọ̀fọ̀ ọmọ rẹ̀ fún ̀pọ̀lọpọ̀ ọjọ́. 35 Gbogbo àwọn ọmọ rẹ̀ lọ́kùnrin, lóbìnrin láti ú nínú, ṣùgbọ́n gbà. Ó , "Rárá, nínú ̀fọ̀ yìí ni èmi yóò lọ isà òkú lọ́dọ̀ ọmọ mi." Baba Josẹfu sọkún fún un.

36 gbogbo àkókò wọ̀nyí, àwọn ará Midiani ta Josẹfu Ejibiti fún Potifari, ̀kan nínú àwọn ìjòyè Farao, í ṣe olórí ̀ṣọ́.

Veja também