Pular para o conteúdo
Publicidade

Gênesis 39

Josẹfu àti aya Potifari

1 39.1,2,21: Ap 7.9. Nígbà wọ́n Josẹfu Ejibiti, Potifari, ará Ejibiti i ṣe ̀kan nínú àwọn ìjòyè Farao. Òun ni olórí àwọn ọmọ-ogun Farao. Ó ra Josẹfu lọ́wọ́ àwọn ará Iṣmaeli wọ́n un lọ síbẹ̀.

2 Olúwa pẹ̀Josẹfu, ó bùkún un, ó ń gbé ilé ̀rẹ̀ ará Ejibiti. 3 Nígbà ̀rẹ̀ i Olúwa pẹ̀rẹ̀, àti Olúwa jẹ́ ó máa ṣe àṣeyọrí nínú ohun gbogbo ó dáwọ́ rẹ̀ . 4 Josẹfu ojúrere Potifari, ó di aṣojú rẹ̀, Potifari fi Josẹfu ṣe olórí ilé rẹ̀ àti ohun gbogbo ó . 5 Láti ìgbà ó ti fi Josẹfu jẹ olórí ilé rẹ̀ àti ohun ìní rẹ̀ gbogbo, ni Ọlọ́run ti bẹ̀rẹ̀ bùkún àwọn ará Ejibiti nítorí Josẹfu. Ìbùkún Olúwa lórí gbogbo ohun Potifari , nílé àti lóko. 6 Ó fi Josẹfu ṣe àkóso gbogbo ohun ó . ṣe ìyọnu lórí ohunkóhun mọ àyàfi nípa oúnjẹ ó ń jẹ láti ìgbà ó ti fi Josẹfu ṣe àkóso ilé e rẹ̀.

Josẹfu jẹ́ arẹwà ọkùnrin ìdúró àti ìrísí rẹ̀, 7 lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, aya rẹ̀ ṣe àkíyèsí Josẹfu, ó fún un , "mi lòpọ̀!"

8 Ṣùgbọ́n Josẹfu kọ̀, ó fún aya ̀rẹ̀ , "Kíyèsi, Olúwa mi fi ohunkóhun mi nínú ilé yìí, gbogbo ohun ìní rẹ̀ ni ó fi mi lọ́wọ́. 9 ẹni ó mi lọ nínú ilé yìí, ̀mi fi ohunkóhun mi àyàfi ìwọ, í ṣe aya rẹ̀. Báwo ni mo ṣe ṣe ohun búburú yìí, ń ṣẹ̀ Ọlọ́run?" 10 ó tilẹ̀ jẹ́ gbogbo ìgbà ni ó ń tẹnumọ́ èyí fún Josẹfu, Josẹfu kọ̀ láti a lòpọ̀. Ó tilẹ̀ kọ̀ láti máa dúró ni ibi ó .

11 ọjọ́ kan, Josẹfu lọ sínú ilé láti ṣe iṣẹ́, èyíkéyìí nínú àwọn ìránṣẹ́ tòsí. 12 Ó di aṣọ Josẹfu , ó , "mi lòpọ̀!" Ṣùgbọ́n Josẹfu fi aṣọ rẹ̀ sílẹ̀ i lọ́wọ́, ó jáde.

13 Nígbà ó i ó ti fi aṣọ rẹ̀ sílẹ̀ òun lọ́wọ́, ó ti jáde, 14 ó pe àwọn ìránṣẹ́ ilé náà, ó fún wọn , "ó, ọkọ ̀ mi Heberu kan wọlé tọ̀ láti fi ṣe ẹlẹ́. Ó wọlé tọ̀ , láti mi lòpọ̀, ṣùgbọ́n mo kígbe. 15 Nígbà ó gbọ́ mo gbé ohùn mi sókè, mo kígbe, ó jọ̀wọ́ aṣọ rẹ̀ sọ́dọ̀ mi, ó , ó bọ́ sóde."

16 Ó fi aṣọ náà sọ́dọ̀ títí ọkọ rẹ̀ fi . 17 Ó fún un , "Ẹrú ará Heberu o ilé láti fi ṣẹlẹ́láti mi lòpọ̀. 18 Ṣùgbọ́n mo ti kígbe fún ìrànlọ́wọ́, ó kúrò nínú ilé."

19 Nígbà Potifari gbọ́ ̀rọ̀ aya rẹ̀ báyìí ni ẹrú rẹ̀ ṣe aya rẹ̀, ó bínú gidigidi. 20 Ó ju Josẹfu ̀wọ̀n, níbi a ń ju àwọn ẹlẹ́wọ̀n ọba .

Ṣùgbọ́n, nígbà Josẹfu nínú ̀wọ̀n níbẹ̀, 21 39.21: Ap 7.9.Olúwa pẹ̀rẹ̀, ó ṣàánú fún un, ó ó ojúrere àwọn alábojútó ọgbà ̀wọ̀n. 22 Nítorí náà, alábojútó ọgbà ẹlẹ́wọ̀n fi Josẹfu ṣe alákòóso ohun gbogbo ó nínú ̀wọ̀n, àti ohun wọn ń ṣe níbẹ̀. 23 Wọ́náà mikàn nípa gbogbo ohun ó fi abẹ́ àkóso Josẹfu, nítorí Olúwa pẹ̀Josẹfu, ó ń jẹ́ ó ṣe àṣeyọrí nínú ohun gbogbo ó dáwọ́.

Veja também