Publicidade

Gênesis 4

Kaini àti Abeli

1 Adamu aya rẹ̀ Efa lòpọ̀, ó lóyún, ó Kaini. Ó , "Pẹ̀ìrànlọ́wọ́ Olúwa ni mo ọmọ ọkùnrin." 2 Lẹ́yìn náà, ó ọmọkùnrin mìíràn a Abeli.

Abeli jẹ́ darandaran, Kaini jẹ́ àgbẹ̀. 3 Ó ṣe lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, Kaini ọrẹ fún Olúwa nínú èso ilẹ̀ rẹ̀. 4 Ṣùgbọ́n Abeli ẹran ó sanra fún Olúwa nínú àkọ́ẹran ̀sìn rẹ̀. Olúwa fi ojúrere wo Abeli àti ọrẹ rẹ̀, 5 ṣùgbọ́n Olúwa fi ojúrere wo Kaini àti ẹbọ rẹ̀. Nítorí náà inú Kaini gidigidi, ojú rẹ̀ fàro.

6 Nígbà náà ni Olúwa bi Kaini , "Èéṣe ìwọ ń bínú? Èéṣe ojú rẹ fàro? 7 ìwọ ṣe ohun ó tọ́, ṣé ìwọ jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà? Ṣùgbọ́n ìwọ ṣe ohun ó tọ́, ̀ṣẹ̀ ń bẹ ẹnu-ọ̀rẹ, ó fẹ́ ìní, ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ ṣe àkóso rẹ̀."

8 Kaini fún Abeli arákùnrin rẹ̀ , "Jẹ́ a lọ oko." Ó ṣe, wọ́n ti oko; Kaini da ojú ìjà kọ Abeli arákùnrin rẹ̀, ó pa á.

9 Nígbà náà ni Olúwa béèrè lọ́wọ́ Kaini , "Níbo ni Abeli arákùnrin rẹ ?"

Ó dáhùn , "Èmi mọ ibi ó , èmí ha ń ṣe olùṣọ́ arákùnrin mi ?"

10 Olúwa , "Kín ni ohun ìwọ ṣe yìí? Gbọ́! ̀jẹ̀ arákùnrin rẹ ń kígbe láti ilẹ̀ . 11 Láti ìsinsin yìí lọ, ìwọ ti lábẹ́ ègún, a ti lórí ilẹ̀ ó ya ẹnu gba ̀jẹ̀ arákùnrin rẹ lọ́wọ́ rẹ. 12 ìwọ ro ilẹ̀, ilẹ̀ yóò fi agbára rẹ̀ so èso rẹ̀ fún mọ́. Ìwọ yóò jẹ́ ìsáǹsá àti alárìnkiri ni orí ilẹ̀ ayé."

13 Kaini fún Olúwa , "Ẹrù ìyà ̀ṣẹ̀ mi pọ̀ ju èyí mo le lọ. 14 Lónìí, ìwọ mi kúrò lórí ilẹ̀, di ẹni ó fi ara pamọ́ kúrò ojú rẹ, èmi yóò di ìsáǹsá àti alárìnkiri ayé, ẹnikẹ́ni ó mi, yóò pa ."

15 Ṣùgbọ́n, Olúwa fún , "Bẹ́̀ kọ́, ẹnikẹ́ni pa Kaini, èmi yóò gbẹ̀san ara onítọ̀hún ìgbà méje." Nígbà náà ni Ọlọ́run fi àmì ara Kaini, ẹnikẹ́ni ó ri ba à pa á. 16 Kaini kúrò níwájú Olúwa, ó ń gbé ilẹ̀ Nodi ìhà ìlà-oòrùn Edeni.

17 Kaini aya rẹ̀ lòpọ̀, ó lóyún, ó Enoku. Kaini tẹ ìlú kan , ó fi orúkọ ọmọ rẹ̀ ọkùnrin Enoku sọ ìlú náà. 18 Enoku Iradi, Iradi ni baba Mehujaeli, Mehujaeli Metuṣaeli, Metuṣaeli ni baba Lameki.

19 Lameki fẹ́ aya méjì, orúkọ èkínní ni Adah, àti orúkọ èkejì ni Silla. 20 Adah Jabali, òun ni baba irú àwọn ń gbé inú àgọ́, wọ́n ń sin ẹran ̀sìn. 21 Orúkọ arákùnrin rẹ̀ ni Jubali, òun ni baba irú àwọn ń tẹ dùùrù wọ́n ń fọn fèrè. 22 Silla náà ọmọkùnrin ń jẹ́ Tubali-Kaini, ó ń rọ oríṣìíríṣìí ohun èlò láti ara idẹ àti irin. Arábìnrin Tubali-Kaini ni Naama.

23 Lameki fún àwọn aya rẹ̀,

"Adah àti Silla, tẹ́mi;

̀yin aya Lameki, gbọ́ ̀rọ̀ mi.

Mo ti pa ọkùnrin kan ó kọlù ,

̀dọ́mọkùnrin ó pa lára.

24 a ó gbẹ̀san Kaini ìgbà méje,

ǹjẹ́ a gba ti Lameki nígbà mẹ́tàdínlọ́gọ́rin (77)."

25 Adamu tún aya rẹ̀ lòpọ̀, ó ọmọkùnrin kan ó pe orúkọ rẹ̀ Seti, ó túmọ̀ , "Ọlọ́run fún mi ọmọkùnrin mìíràn ipò Abeli Kaini pa." 26 Seti náà ọmọkùnrin kan, ó pe orúkọ rẹ̀ Enoṣi.

Láti àkókò náà lọ ni àwọn ènìyàn ti bẹ̀rẹ̀ pe orúkọ Olúwa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-