Publicidade

Gênesis 41

Àwọn àlá Farao

1 Nígbà odindi ọdún méjì ti kọjá, Farao àlá: ó ara rẹ̀ dúró etí odò Naili. 2 Nígbà náà ni màlúù méje jáde láti inú odò, wọ́n dára láti , wọ́n sanra, wọ́n ń jẹ koríko. 3 Lẹ́yìn àwọn wọ̀nyí, ni àwọn màlúù méje mìíràn lẹ́ó jáde láti inú odò Naili, wọ́n dúró ti àwọn méje ó sanra ó bèbè odò náà. 4 Àwọn màlúù ó , lẹ́gbé àwọn ó lẹ́ó sanra jẹ. Nígbà náà ni Farao .

5 Ó tún padà sùn, ó àlá mìíràn: ó síírí ọkà méje ó kún, ó yómọ, ó dára, ó jáde lára igi ọkà kan ṣoṣo. 6 Lẹ́yìn wọn ni síírí ọkà méje mìíràn yọ, wọn yómọ, afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn ti rẹ̀ ́ dànù. 7 Àwọn síírí ọkà méje yómọ (ọmọ rẹ̀ tóbi) wọ̀nyí gbé àwọn ó yómọ (ọmọ rẹ̀ tóbi) . Nígbà náà ni Farao lójú oorun, ó i àlá ni.

8 41.8: Da 2.2. òwúrọ̀, ọkàn rẹ̀ dàrú, nítorí náà, ó ránṣẹ́ pe gbogbo àwọn onídán àti ̀mọ̀ran ilẹ̀ Ejibiti. Farao rọ́ àlá rẹ̀ fún wọn, ṣùgbọ́n ̀kan nínú wọn ó le sọ ìtumọ̀ àlá náà fún un.

9 Nígbà náà ni olórí agbọ́fún Farao , "Lónìí ni mo rántí ̀ṣẹ̀ mi. 10 Nígbà kan Farao bínú àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, ó fi èmi àti olórí alásè sínú ̀wọ̀n ilé olórí ̀ṣọ́. 11 ̀kọ̀̀kan wa àlá, àlá kọ̀̀kan ìtumọ̀ tirẹ̀. 12 Ọmọkùnrin ará Heberu kan ó jẹ́ ìránṣẹ́ olórí ̀ṣọ́ níbẹ̀ pẹ̀wa. A rọ́ àwọn àlá wa fún un, ó túmọ̀ wọn fún wa, ó sọ ìtumọ̀ àlá ẹnìkọ̀̀kan fún un. 13 ó ti túmọ̀ àlá wọ̀nyí náà ni ohun gbogbo . A mi padà ipò mi, a so ọkùnrin kejì kọ́ sórí ̀wọ̀n."

14 Nítorí náà Farao ránṣẹ́ pe Josẹfu, wọn un kíákíá láti inú ìhámọ́. Nígbà ó irun rẹ̀, ó pààrọ̀ aṣọ rẹ̀, ó síwájú Farao.

15 Farao fún Josẹfu, "Mo àlá kan, ẹni o le è túmọ̀ rẹ̀. Ṣùgbọ́n mo ti gbọ́ nípa rẹ o ti gbọ́ àlá, o le è túmọ̀ rẹ̀."

16 Josẹfu Farao ohùn , "í ṣe agbára mi, ṣùgbọ́n, Ọlọ́run ni yóò fi ìdáhùn àlàáfíà fún Farao ìtumọ̀ àlá náà."

17 Nígbà náà ni Farao fún Josẹfu , "inú àlá mi, mo dúró ni etí bèbè odò Naili, 18 kíyèsi i, màlúù méje ó sanra o lẹ́jáde , wọ́n ń jẹ koríko tòsí ibẹ̀. 19 Lẹ́yìn wọn, màlúù méje mìíràn jáde , wọ́n hángógó, wọn lẹ́bẹ́̀ n ì irú màlúù ó ṣe àìlẹ́bẹ́̀ ilẹ̀ Ejibiti. 20 Àwọn màlúù ó lẹ́jẹ àwọn màlúù ó sanra ó kọ́ jáde nínú odò. 21 Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà wọ́n jẹ́ wọ́n tan, ẹni ó le mọ̀ wọ́n jẹ ohunkóhun, nítorí wọn sanra i, wọn bùrẹ́síbẹ̀. Nígbà náà ni mo tají.

22 "ojú àlá mi, mo tún síírí ọkà méje ó ọmọ ó dára, wọ́n jáde láti ara igi ọkà kan. 23 Lẹ́yìn wọn, àwọn méje mìíràn yọ jáde, ọmọ bẹ́̀ ni afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn ti rẹ̀ ́ dànù tán. 24 Àwọn síírí ọkà méje yómọ gbé àwọn méje ó dára wọ̀nyí . Mo sọ àlá yìí fún àwọn onídán mi, ṣùgbọ́n ẹni ó le túmọ̀ rẹ̀ fún mi."

25 Nígbà náà ni Josẹfu fún Farao, "Ìtumọ̀ kan náà ni àwọn àlá méjèèjì . Ọlọ́run fi ohun ó fẹ́ ṣe hàn fún Farao. 26 Àwọn màlúù méje ti ó dára jẹ́ ọdún méje, síírí ọkà méje ó dára náà jẹ́ ọdún méje: ̀kan ṣoṣo ni wọn, àlá kan náà ni. 27 Àwọn màlúù méje sanra, rẹwà ó jáde gbẹ̀yìn jẹ́ ọdún méje, bẹ́̀ náà ni síírí ọkà méje dára, afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn ti rẹ̀ dànù tan, wọn jẹ́ ọdún méje ìyàn yóò fi .

28 "mo ti fún Farao ìṣáájú náà ni: Ọlọ́run fi ohun yóò ṣẹlẹ̀ han Farao. 29 Ọdún méje oúnjẹ yóò pọ̀ yanturu ń bọ̀ Ejibiti. 30 Ṣùgbọ́n ọdún méje mìíràn ìyàn yóò ń bọ̀, nígbà náà ni a ó tilẹ̀ gbàgbé gbogbo ̀pọ̀ ilẹ̀ Ejibiti, ìyàn yóò run gbogbo ilẹ̀ náà. 31 A rántí àsìkò ̀pọ̀ oúnjẹ yanturu náà mọ́ nítorí ìyàn yóò tẹ̀e yóò pọ̀ púpọ̀. 32 Ìdí Ọlọ́run fi fi àlá náà han fún Farao ̀méjì ̀tọ̀̀tọ̀ ni , Ọlọ́run ti pinnu yóò ṣẹlẹ̀ bẹ́̀ dandan, àti ni pẹ́ Ọlọ́run yóò fi ṣe é.

33 "Ìmọ̀ràn mi ni , jẹ́ Farao ọlọ́gbọ́n ènìyàn kan ilẹ̀ Ejibiti, ó fi ṣe alákòóso iṣẹ́ àgbẹ̀ ilẹ̀ Ejibiti. 34 Farao yan àwọn alábojútó láti máa gba ìdámárùn-ún ìkórè oko ilẹ̀ Ejibiti àsìkò ọdún méje ̀pọ̀. 35 wọn gbogbo oúnjẹ ilẹ̀ náà ni àwọn ọdún méje ̀pọ̀ yìí, wọn àwọn ọkà wọn jẹ ṣẹ́pamọ́ lábẹ́ àṣẹ Farao. a wọn pamọ́ ni àwọn ìlú fún jíjẹ. 36 wọn oúnjẹ náà pamọ́ fún orílẹ̀-èdè yìí, a ba à le ó ni ọdún méje ìyàn yóò fi ilẹ̀ Ejibiti, ìyàn náà ba à pa orílẹ̀-èdè yìí run."

37 Èrò náà dára lójú Farao àti àwọn ìjòyè rẹ̀. 38 Farao bi wọ́n , "Ǹjẹ́ a le ẹnikẹ́ni bi ọkùnrin yìí, nínú ẹni ̀Ọlọ́run ń gbé?"

39 Nígbà náà ni Farao fún Josẹfu, "Níwọ́n Ọlọ́run ti fi gbogbo èyí hàn ́, ẹni náà ó gbọ́n ó mọ̀ràn i tìrẹ ilẹ̀ Ejibiti yìí, 40 ìwọ yóò ṣe àkóso ààfin mi gbogbo àwọn ènìyàn gbọdọ̀ tẹríba fún àṣẹ ̀ rẹ. Ìtẹ́ mi nìkan ni èmi yóò fi ́ lọ."

Josẹfu di alábojútó ilẹ̀ Ejibiti

41 Farao fún Josẹfu , "Mo fi ́ ṣe alábojútó gbogbo ilẹ̀ Ejibiti." 42 41.42: Da 5.29.Farao bọ́ òrùka èdìdì ọwọ́ rẹ̀, ó fi wọ Josẹfu ó wọ̀ ́ aṣọ ̀gbọ̀ dáradára, ó fi ̀gbà ó dára i lọ́rùn. 43 Ó un ó gun kẹ̀kẹ́-ẹṣin igbákejì ara rẹ̀, àwọn ènìyàn ń pariwo níwájú rẹ̀ , "yàgò lọ́." Báyìí ni ó fi ṣe alábojútó gbogbo ilẹ̀ Ejibiti.

44 Nígbà náà ni Farao fún Josẹfu , "Èmi ni Farao. Ṣùgbọ́n láìsí àṣẹ rẹ, ẹnikẹ́ni gbọdọ̀ ṣe ohunkóhun ilẹ̀ Ejibiti." 45 Farao sọ Josẹfu orúkọ yìí Safenati-Panea (èyí ó túmọ̀ ẹni ó ni agbára ikú àti ìyè ìkáwọ́ òrìṣà). Ó fun un Asenati ọmọ Potifẹra, alábojútó òrìṣà Oni, gẹ́gẹ́ aya. Josẹfu rin gbogbo ilẹ̀ Ejibiti .

46 Ọmọ ọgbọ̀n ọdún ni Josẹfu nígbà ó wọ iṣẹ́ Farao ọba Ejibiti. Josẹfu jáde kúrò níwájú Farao, ó ṣe ìbẹ̀káàkiri gbogbo ilẹ̀ Ejibiti. 47 ọdún méje ̀pọ̀, ilẹ̀ náà so èso lọ́pọ̀lọ́pọ̀. 48 Josẹfu gbogbo oúnjẹ a pèsè ni ilẹ̀ Ejibiti ọdún méje ̀pọ̀ yìí, ó pa wọ́n mọ́ àwọn ìlú. ìlú kọ̀̀kan ni ó gbogbo oúnjẹ wọ́n gbìn àyíká ìlú wọn . 49 Josẹfu pa ̀pọ̀lọpọ̀ ọkà mọ́ iyanrìn Òkun; ó pọ̀ bẹ́̀ gẹ́́ ṣe àkọsílẹ̀ mọ́ nítorí, ó tayọ kíkà.

50 ó di ọdún ìyàn , Asenati ọmọ Potifẹra alábojútó Oni ọmọkùnrin méjì fún Josẹfu. 51 Josẹfu sọ orúkọ àkọ́rẹ̀ ni Manase, ó , "Nítorí Ọlọ́run ti mi gbàgbé gbogbo ìdààmú mi àti gbogbo ilé baba mi." 52 Ó sọ orúkọ èkejì Efraimu, ó , "Nítorí Ọlọ́run fún mi ọmọ ilẹ̀ ìpọ́njú mi."

53 Ọdún méje ̀pọ̀ oúnjẹ òpin ilẹ̀ Ejibiti, 54 41.54: Ap 7.11.ọdún méje ìyàn bẹ̀rẹ̀, Josẹfu ti gan an. Ìyàn gbogbo ilẹ̀ tókù, ṣùgbọ́n oúnjẹ gbogbo ilẹ̀ Ejibiti. 55 41.55: Jh 2.5.Nígbà àwọn ará Ejibiti bẹ̀rẹ̀ ipá ìyàn náà, wọ́n kígbe Farao. Nígbà náà ni Farao fún wọn , "lọ Josẹfu, ṣe ohun ó fún un yín."

56 Nígbà ìyàn ti tàn gbogbo ilẹ̀ náà, Josẹfu ṣí inú àká, ó bẹ̀rẹ̀ ta ọkà fún àwọn ènìyàn, nítorí ìyàn náà gan an gbogbo ilẹ̀ Ejibiti. 57 Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ń Ejibiti láti ra oúnjẹ lọ́wọ́ Josẹfu, nítorí ìyàn náà pọ̀ gidigidi káàkiri gbogbo ayé.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-