Pular para o conteúdo
Publicidade

Gênesis 45

5 Ṣùgbọ́n báyìí, ṣe banújẹ́, ṣe bínú ara yín títà ìhín, nítorí, ̀àti gba ̀yín ni Ọlọ́run ṣe rán mi ìhín ṣáájú yín. 6 Ìyàn ó ti láti ọdún méjì sẹ́yìn yìí yóò tẹ̀síwájú fún ọdún márùn-ún i nínú èyí ẹnikẹ́ni gbìn, bẹ́̀ ni wọn ni kórè. 7 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run rán mi ṣáájú yín ìhín láti da irú-ọmọ yín fún un yín lórí ilẹ̀ ayé àti láti fi ìgbàlà ńlá gba ̀yín .

8 "Nítorí náà, í ṣe ̀yin ni ó rán mi ibí yìí, ṣe Ọlọ́run. Ó fi ṣe baba, Olùdámọ̀ràn fún Farao, olúwa fún gbogbo ilé Farao àti alákòóso gbogbo ilẹ̀ Ejibiti.

Veja também