Publicidade

Gênesis 6

Ìkún omi

1 6.1-4: Jb 1.6; 2.1. Nígbà ènìyàn bẹ̀rẹ̀ pọ̀ si orí ilẹ̀, wọ́n àwọn ọmọbìnrin. 2 Àwọn ọmọ Ọlọ́run i àwọn ọmọbìnrin ènìyàn lẹ́, wọ́n fẹ́ èyíkéyìí ó wọ́n ṣe aya. 3 Nígbà náà ni Olúwa , "Èémí ìyè mo sínú ènìyàn máa gbé inú ènìyàn títí láé, nítorí ẹran-ara à ni òun, ọgọ́ọdún ni ọjọ́ rẹ̀ yóò jẹ́."

4 6.4: Nu 13.33. Àwọn òmíràn láyé ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, àti lẹ́yìn ìgbà náà; nígbà àwọn ọmọ Ọlọ́run lọ àwọn ọmọbìnrin ènìyàn lòpọ̀ wọ́n bímọ fún wọn. Àwọn náà ni ó di akọni àti olókìkí ìgbà náà.

5 Olúwa ìwà búburú ènìyàn ti ń gbilẹ̀ si, àti gbogbo èrò inú rẹ̀ kìkì ibi ni, ìgbà gbogbo. 6 Inú Olúwa bàjẹ́ gidigidi nítorí ó ènìyàn ayé, ọkàn rẹ̀ gbọgbẹ́. 7 Nítorí náà, Olúwa , "Èmi yóò pa ènìyàn mo ti run kúrò lórí ilẹ̀, ènìyàn àti ẹranko, àti ohun ń rákò, àti ẹyẹ ojú ̀run, nítorí inú mi bàjẹ́ mo ti wọn." 8 Ṣùgbọ́n, Noa ojúrere Olúwa.

Noa àti ìkún omi

9 6.9: 2Pt 2.5. Wọ̀nyí ni ìtàn Noa.

Noa nìkan ni ó jẹ́ olóòótọ́ ènìyàn àti ẹni ó ìgbà ayé rẹ̀, ó fi òtítọ́ Ọlọ́run rìn. 10 Noa ọmọkùnrin mẹ́ta, Ṣemu, Hamu àti Jafeti.

11 Ayé kún fún ìbàjẹ́ gidigidi ojú Ọlọ́run, ó kún fún ìwà ipá pẹ̀. 12 Ọlọ́run ayé ti bàjẹ́ , nítorí àwọn ènìyàn inú ayé ti ara wọn jẹ́ gbogbo ̀wọn. 13 Ọlọ́run fún Noa , "Èmi yóò pa gbogbo ènìyàn run, nítorí ilẹ̀ ayé kún fún ìwà ipá nípasẹ̀ wọn. Èmi yóò pa wọ́n run àti ayé pẹ̀. 14 Nítorí náà fi igi ̀mọ̀ kan ọkọ̀, o yọ yàrá inú rẹ̀, o fi ̀ilẹ̀ rẹ́ tinú-tẹ̀yìn. 15 Báyìí ni ìwọ yóò ṣe kan ọkọ̀ náà: Gígùn rẹ̀ òró yóò jẹ́ ̀́dúnrún (300) ìgbọ̀nwọ́, ìbú rẹ̀ yóò jẹ́ àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́, nígbà gíga rẹ̀ yóò jẹ́ ọgbọ̀n ìgbọ̀nwọ́. 16 Ṣe òrùlé orí ọkọ̀ náà ìgbọ̀nwọ́ kan, ṣe ọkọ̀ náà alájà mẹ́ta, ipá kan ìsàlẹ̀, ̀kan àárín àti ̀kan ó òkè, ̀gbẹ́ ni ó ṣe ẹnu-ọ̀ọkọ̀ náà . 17 Èmi yóò ìkún omi ayé láti pa gbogbo ohun ẹlẹ́mìí run lábẹ́ ̀run. Gbogbo ̀ó èémí ìyè inú. Gbogbo ohun ó nínú ayé yóò parun. 18 Ṣùgbọ́n èmi ó májẹ̀mi pẹ̀rẹ, ìwọ yóò wọ ọkọ̀, ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ pẹ̀aya rẹ. 19 Ìwọ yóò gbogbo ohun alààyè takọ tabo inú ọkọ̀, wọn le láààyè pẹ̀rẹ. 20 onírúurú àwọn ẹyẹ, ẹranko àti àwọn ohun ń rákò méjì méjì, a pa wọ́n mọ́ láààyè. 21 onírúurú oúnjẹ sínú ọkọ̀, o pa wọ́n mọ́ fún jíjẹ gbogbo ̀yin nínú ọkọ̀ àti ènìyàn àti ẹranko."

22 6.22: Hb 11.7. Noa ṣe ohun gbogbo Ọlọ́run ti pàṣẹ fún un.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-