Publicidade

Gênesis 9

Májẹ̀Ọlọ́run pẹ̀Noa

1 Ọlọ́run súre fún Noa àti àwọn ọmọ rẹ̀ , "máa i, pọ̀ iye, kún ayé. 2 ̀yín yóò ojo lára gbogbo ẹranko àti gbogbo ẹyẹ ojú ̀run, àti gbogbo àwọn ̀ń rìn nílẹ̀; àti gbogbo ẹja òkun; a fi wọ́n e yín lọ́wọ́. 3 Gbogbo ohun láààyè ó ń rìn, ni yóò jẹ́ oúnjẹ fún un yín, mo ṣe fi ewéko fún un yín náà ni mo fi ohun gbogbo fún un yín.

4 "Ṣùgbọ́n ̀yin gbọdọ̀ jẹ ẹran tòun-tẹ̀jẹ̀ rẹ̀. 5 Nítòótọ́ ̀jẹ̀ yín, àní ̀yín, ni èmi yóò béèrè; lọ́wọ́ gbogbo ẹranko ni èmí yóò béèrè rẹ̀, àti lọ́wọ́ ènìyàn, lọ́wọ́ arákùnrin olúkúlùkù ènìyàn ni èmi yóò béèrè ̀ènìyàn.

6 "Ẹnikẹ́ni ó ta ̀jẹ̀ ènìyàn sílẹ̀,

láti ọwọ́ ènìyàn ni a ó gbà ta ̀jẹ̀ rẹ̀ sílẹ̀.

Nítorí àwòrán Ọlọ́run

ni Ọlọ́run ènìyàn.

7 Ṣùgbọ́n tiyín, máa i, máa pọ̀ i, máa gbá yìn lórí ilẹ̀, pọ̀ i lórí rẹ̀."

8 Ọlọ́run fún Noa àti àwọn ọmọ rẹ̀ , 9 "Mo májẹ̀mi pẹ̀yín àti pẹ̀àwọn ìran yín ń bọ̀ lẹ́yìn. 10 Àti pẹ̀gbogbo ̀alààyè ó pẹ̀yín, ìbá à ṣe ẹyẹ, ẹja, ẹran ̀sìn, ẹranko igbó, gbogbo ohun ó jáde kúrò nínú ọkọ̀ pẹ̀yín, àní gbogbo ̀alààyè ayé. 11 Mo májẹ̀mi pẹ̀yín láéláé, Èmi yóò fi ìkún omi pa ayé run kúrò mọ láéláé, a yóò fi omi pa ayé run."

12 Ọlọ́run , "Èyí ni àmì májẹ̀mo ń yìí láàrín èmi àti ̀yin àti ̀alààyè ó pẹ̀yín, májẹ̀àtìrandíran ń bọ̀: 13 Mo ti fi òṣùmàrè àwọsánmọ̀, yóò jẹ́ àmì májẹ̀láàrín èmi àti ayé. 14 Nígbàkígbà mo òjò ṣú, òṣùmàrè farahàn àwọsánmọ̀. 15 Èmi yóò rántí májẹ̀mi, ó láàrín èmi àti ̀yin àti gbogbo ̀alààyè, yóò tún ìkún omi mọ́ láti pa gbogbo ̀run. 16 Nígbàkígbà òṣùmàrè yọ àwọsánmọ̀, èmi yóò i, èmi yóò rántí májẹ̀ayérayé ń bẹ láàrín Ọlọ́run àti gbogbo ̀alààyè ń bẹ ayé."

17 Ọlọ́run fún Noa , "Èyí ni àmì májẹ̀mo ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ láàrín èmi àti gbogbo alààyè ayé."

Àwọn ọmọ Noa

18 Àwọn ọmọ Noa ó jáde nínú ọkọ̀ ni Ṣemu, Hamu àti Jafeti. (Hamu ni baba Kenaani.) 19 Láti ̀dọ̀ àwọn ọmọ Noa mẹ́tẹ̀̀ta yìí ni gbogbo ènìyàn ti tàn gbogbo ilẹ̀ ayé.

20 Noa bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ àgbẹ̀, ó gbin ọgbà àjàrà. 21 Ó mu àmupara nínú ọtí wáìnì àjàrà rẹ̀, ó ara rẹ̀ ìhòhò, ó sùn nínú àgọ́ rẹ̀. 22 Hamu í ṣe baba Kenaani baba rẹ̀ ìhòhò bẹ́̀ ni ó lọ sọ fún àwọn arákùnrin rẹ̀ méjèèjì ìta. 23 Ṣùgbọ́n Ṣemu àti Jafeti aṣọ èjìká wọn, wọ́n fi ̀yìn rìn, wọ́n bo ìhòhò baba wọn. Wọ́n kọjú sẹ́yìn wọn ó ba à ìhòhò baba wọn.

24 Nígbà Noa kúrò ojú ọtí, ó mọ ohun ọmọ rẹ̀ kékeré ṣe i. 25 Ó ,

"Ègún ni fún Kenaani.

Ìránṣẹ́ àwọn ìránṣẹ́ ni yóò máa ṣe

fún àwọn arákùnrin rẹ̀."

26 Ó tún ,

"Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Ṣemu

Kenaani yóò máa ṣe ẹrú fún Ṣemu.

27 Ọlọ́run yóò Jafeti gbilẹ̀,

Jafeti yóò máa gbé àgọ́ Ṣemu

Kenaani yóò jẹ́ ẹrú fún un."

28 Noa láààyè fún irinwó ọdún dín àádọ́ta (350) lẹ́yìn ìkún omi. 29 Àpapọ̀ ọjọ́ ayé Noa jẹ́ ẹgbẹ̀rún ọdún dín làádọ́ta (950), ó .

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-