Pular para o conteúdo
Publicidade

Jobu 41

Ọlọ́run ń tẹ̀síwájú láti pe Jobu níjà

1 "Ǹjẹ́ ìwọ le è fi ìwọ̀ fa Lefitani jáde?

Tàbí ìwọ fi okùn so ahọ́n rẹ̀ mọ́lẹ̀?

2 Ìwọ fi okùn bọ̀ ́ í ,

tàbí fi ìwọ̀ ̀gún gun ̀rẹ̀kẹ́?

3 Òun ha jẹ́ bẹ ̀bẹ̀ fún àánú lọ́dọ̀

rẹ ̀pọ̀lọpọ̀ òun ha sọ̀rọ̀ pẹ̀lẹ́?

4 Òun ha májẹ̀?

Ìwọ ó ha máa ṣe ẹrú láéláé ?

5 Ìwọ ha ba sáré ẹni ẹyẹ ni,

tàbí ìwọ ó é fún àwọn ọmọbìnrin ìránṣẹ́ rẹ̀?

6 Ẹgbẹ́ àwọn apẹja yóò ha máa á ?

Wọn ó ha pín láàrín àwọn oníṣòwò?

7 Ìwọ ha fi ̀kọ̀-irin gun awọ rẹ̀,

tàbí orí rẹ̀ pẹ̀̀kọ̀ ìpẹja.

8 Fi ọwọ́ rẹ e lára,

ìwọ ó rántí ìjà náà, ìwọ yóò ṣe bẹ́̀ mọ́.

9 Kíyèsi, ìgbìyànjú láti un asán;

kìkì ìrí rẹ̀ ara yóò ha rọ̀ ́ wẹ̀?

10 ẹni aláyà lílé ó ru sókè.

Ǹjẹ́ ta ni ó dúró níwájú mi.

11 Ta ni ó kọ́kọ́ ṣe fún mi, èmi ìbá fi san án fún un?

Ohunkóhun ti ń bẹ lábẹ́ ̀run gbogbo, tèmi ni.

12 "Èmi yóò fi ̀ara Lefitani,

tàbí ipá rẹ, tàbí ìhámọ́ra rẹ ó ẹwà pamọ́.

13 Ta ni yóò rídìí aṣọ àpáta rẹ̀?

Tàbí ta ni ó súnmọ́ ̀méjì eyín rẹ̀?

14 Ta ni ó ṣí ìlẹ̀kùn iwájú rẹ̀?

Àyíká ̀yin rẹ ni ìbẹ̀ńlá.

15 Ìpẹ́ lílé ìgbéraga rẹ̀;

ó pàdé pọ̀ tímọ́tímọ́ àmì èdìdì.

16 Èkínní fi ara mọ́ èkejì bẹ́̀

afẹ́fẹ́ wọ àárín wọn.

17 Èkínní fi ara mọ́ èkejì rẹ̀;

wọ́n wọ́n pọ̀ a mọ̀ wọ́n.

18 Nípa sin rẹ̀ ìmọ́lẹ̀ á mọ́,

ojú rẹ̀ a dàbí ìpéǹpéjú òwúrọ̀.

19 Láti ẹnu rẹ ni ̀wọ́-iná ti jáde ,

ìpẹ́pẹ́ iná a ta jáde.

20 Láti ihò imú rẹ ni èéfín ti jáde ,

ẹni láti inú ìkòkò a fẹ́ iná ìfèéfèé lábẹ́ rẹ̀.

21 Èémí rẹ̀ tiná bọ ̀yin iná,

̀wọ́-iná ti ẹnu rẹ̀ jáde.

22 ọrùn rẹ̀ agbára ,

àti ìbànújẹ́ àyà padà di ayọ̀ níwájú rẹ̀.

23 Jabajaba ẹran rẹ̀ dìjọ pọ̀,

wọ́n múra gírí fún ara wọn, a wọn ipò.

24 Àyà rẹ̀ dúró gbagidi òkúta,

àní, ó le bi ìyá ọlọ.

25 Nígbà ó gbé ara rẹ̀ sókè, àwọn alágbára bẹ̀;

nítorí ìbẹ̀ńlá, wọ́n dààmú.

26 ̀kọ̀ tàbí idà, tàbí ọfà,

ẹni ó ṣá a rán an.

27 Ó irin ibi koríko gbígbẹ

àti idẹ si bi igi híhù.

28 Ọfà un ;

òkúta kànnakánná lọ́dọ̀ rẹ̀ dàbí àgékù koríko.

29 Ó ka ẹṣin àgékù ìdì koríko;

ó rẹ́rìn-ín mímì ̀kọ̀.

30 Òkúta mímú ń bẹ nísàlẹ̀ abẹ́ rẹ̀,

ó tẹ́ ohun mímú ṣóńṣó sórí ẹrẹ̀.

31 Ó ibú omi ìkòkò;

ó sọ̀ agbami òkun dàbí kólòbó ìkunra.

32 Ó ipa ̀tan lẹ́yìn rẹ̀;

ènìyàn a máa ka ibú ewú arúgbó.

33 Lórí ilẹ̀ ayé ẹni ó dàbí rẹ̀,

a láìní ìbẹ̀.

34 Ó bojú wo ohun gíga gbogbo,

ó nìkan jásí ọba lórí gbogbo àwọn ọmọ ìgbéraga."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também