Pular para o conteúdo
Publicidade

Josué 14

Pínpín ilẹ̀ ìhà ìwọ̀-oòrùn Jordani

1 Ìwọ̀nyí ni ilẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli gbà gẹ́gẹ́ ogún ilẹ̀ Kenaani, Eleasari àlùfáà, Joṣua ọmọ Nuni àti olórí ̀àwọn agbo ilé Israẹli pín fún wọn. 2 Ìbò ni a fi pín ìní wọn fún àwọn ̀mẹ́sàn-án ààbọ̀ gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ láti ọwọ́ Mose. 3 Mose ti fún àwọn ̀méjì àti ààbọ̀ ogún wọn ìlà-oòrùn Jordani, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Lefi ni fi ìní fún àárín àwọn ó . 4 Àwọn ọmọ Josẹfu di ̀méjì, Manase àti Efraimu. Àwọn ọmọ Lefi gba ìpín ilẹ̀ náà ṣe àwọn ìlú wọn yóò máa gbé, pẹ̀pápá oko tútù fún ̀wọ́ ẹran àti agbo ẹran wọn. 5 Bẹ́̀ ni àwọn ará Israẹli pín ilẹ̀ náà, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

A fún Kalebu Hebroni

6 Àwọn ọkùnrin Juda ̀dọ̀ Joṣua Gilgali. Kalebu ọmọ Jefunne ti Kenissiti fún un , "Ìwọ rántí ohun Olúwa sọ fún Mose ènìyàn Ọlọ́run Kadeṣi-Barnea nípa ìwọ àti èmi. 7 Mo jẹ́ ọmọ ogójì ọdún nígbà Mose ìránṣẹ́ Olúwa rán mi láti Kadeṣi-Barnea lọ rin ilẹ̀ náà . Mo ìròyìn fún un gẹ́gẹ́ o ti mi lójú, 8 ṣùgbọ́n àwọn arákùnrin mi wọ́n mi lọ àyà àwọn ènìyàn . Ṣùgbọ́n tèmi, èmi fi gbogbo ọkàn tẹ̀Olúwa Ọlọ́run mi. 9 ọjọ́ náà, Mose búra fún mi , Ilẹ̀ ẹsẹ̀ rẹ ti rìn ni yóò jẹ́ ìní rẹ àti ti àwọn ọmọ rẹ láéláé, nítorí ìwọ fi tọkàntọkàn pẹ̀Olúwa Ọlọ́run mi.

10 "Ǹjẹ́ nísinsin yìí, kíyèsi i Olúwa mi gẹ́gẹ́ ó ti , láti ọdún márùndínláàádọ́ta yìí , láti ìgbà Olúwa ti sọ ̀rọ̀ yìí fún Mose, nígbà Israẹli ń rìn kiri nínú aginjù, kíyèsi i nísinsin yìí, èmi nìyìí lónìí, ọmọ àrùndínláàdọ́rùn-ún ọdún. 11 Síbẹ̀ èmi agbára lónìí, ìgbà Mose rán mi jáde. Èmi agbára láti jáde fún ogun nísinsin yìí gẹ́gẹ́ mo ti ìgbà náà. 12 Nísinsin yìí fi ìlú orí òkè fún mi èyí Olúwa ṣe ìlérí fún mi ọjọ́ náà. Ìwọ gbọ́ ìgbà náà àwọn ọmọ Anaki ti ibẹ̀, àti àwọn ìlú wọn tóbi, ó ṣe olódi, ṣùgbọ́n Olúwa ba fẹ́, èmi yóò wọn jáde, gẹ́gẹ́ ó ti sọ."

13 Bẹ́̀ ni Joṣua súre fun Kalebu ọmọ Jefunne ó si fun un Hebroni ni ilẹ̀ ìní. 14 Bẹ́̀ ni Hebroni jẹ́ ti Kalebu ọmọ Jefunne ará Kenissiti láti ìgbà náà, nítorí ó tẹ̀Olúwa Ọlọ́run Israẹli tọkàntọkàn. 15 (Hebroni a máa jẹ́ Kiriati-Arba ̀yìn Arba, èyí ó jẹ́ ènìyàn ńlá nínú àwọn ọmọ Anaki.)

Nígbà náà ni ilẹ̀ náà sinmi ogun.

Veja também