Publicidade

Jó 31

Àwíjàre Jobu

1 "Mo ti ojú mi májẹ̀,

èmi ha ṣe tẹjúmọ́ wúńdíá?

2 Nítorí ni ìpín Ọlọ́run láti ̀run ?

Tàbí ni ogún Olódùmarè láti òkè ̀run .

3 ṣe àwọn ènìyàn búburú ni ìparun fún,

àti àjàkálẹ̀-ààrùn fún àwọn oníṣẹ́ ̀ṣẹ̀?

4 Òun ha ri ipa ̀mi,

òun ha ka gbogbo ìṣísẹ̀ mi?

5 "ó ṣe èmi fi àìṣòótọ́ rìn,

tàbí ẹsẹ̀ mi yára ̀tàn,

6 (jẹ́ Ọlọ́run wọ́n nínú ìwọ̀n òdodo,

Ọlọ́run le mọ ìdúró ṣinṣin mi.)

7 ẹsẹ̀ kúrò lójú ̀,

àyà tẹ̀ipa ojú mi,

tàbí àbàwọ́n kan lẹ̀ mọ́ mi ọwọ́,

8 ǹjẹ́ èmi ó gbìn ẹlòmíràn ó mújẹ,

àní a fa irú-ọmọ mi tu.

9 "àyà mi di fífà ipasẹ̀ obìnrin kan,

tàbí mo lọ í ba de ènìyàn ẹnu-ọ̀ilé aládùúgbò mi,

10 àyà mi ó lọ ọlọ fún ẹlòmíràn,

àwọn ẹlòmíràn ó tẹ̀ ara wọn ara rẹ̀.

11 Nítorí yóò jẹ́ ohun ìtìjú àní,

̀ṣẹ̀ a ó ṣe onídàájọ́ rẹ̀.

12 Nítorí iná èyí ó ibi ìparun,

ìbá fa gbòǹgbò ohun ìbísí mi gbogbo tu.

13 "mo ṣe àìka ̀ràn ìránṣẹ́kùnrin mi

tàbí ìránṣẹ́bìnrin mi ,

nígbà wọ́n ń mi ;

14 ni èmi ó ha ṣe nígbà Ọlọ́run dìde?

Nígbà ó ṣe ìbẹ̀, ohùn ni èmi ó ?

15 Ẹni ó mi inú kọ́ ni ó a?

Ẹnìkan náà ó mọ inú ìyá wa?

16 "mo fa ọwọ́ sẹ́yìn fún ìfẹ́ inú tálákà,

tàbí mo ojú opó rẹ̀wẹ̀,

17 tàbí mo nìkan bu òkèlè mi jẹ,

aláìní baba jẹ nínú rẹ̀;

18 nítorí láti ìgbà èwe mi ni a ti tọ́ dàgbà pẹ̀mi ẹni baba,

èmi ń ṣe ìtọ́opó láti inú ìyá mi :

19 èmi olùpọ́njú láìní aṣọ,

tàbí tálákà kan láìní ìbora;

20 ọkàn rẹ̀ súre fún mi,

tàbí ara rẹ̀ gbóná nípasẹ̀ irun àgùntàn mi;

21 mo gbé ọwọ́ mi sókè aláìní baba,

nítorí mo ìrànlọ́wọ́ mi ẹnu ibodè,

22 ǹjẹ́, apá mi o wọ́n kúrò ihò èjìká rẹ̀,

apá mi ó ṣẹ́ láti egungun rẹ̀ .

23 Nítorí ìparun láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ni ̀ńlá fún mi,

àti nítorí ọláńlá rẹ̀ èmi le è dúró.

24 "ó ṣe mo fi wúrà ṣe ìgbẹ́kẹ̀mi,

tàbí mo fún fàdákà dídára , Ìwọ ni ààbò mi,

25 mo yọ̀ nítorí ọrọ̀ pọ̀,

àti nítorí ọwọ́ mi dara lọ́pọ̀lọ́pọ̀,

26 mo bojú wo oòrùn nígbà ń ràn,

tàbí òṣùpá ń ràn nínú ìtànmọ́lẹ̀,

27 a tàn ọkàn mi jẹ

láti fi ẹnu mi ọwọ́ mi,

28 èyí pẹ̀ni ̀ṣẹ̀ ti àwọn onídàájọ́ láti bẹ̀,

nítorí èmí yóò jẹ́ aláìṣòótọ́ Ọlọ́run ó lókè.

29 "ó ṣe mo yọ̀ ìparun ẹni ó kórìíra mi.

Tàbí mo gbéraga sókè, nígbà ibi a.

30 Bẹ́̀ èmi jẹ ki ẹnu mi ki ó ṣẹ̀

nípa fífẹ́ ègún ọkàn rẹ̀.

31 àwọn ènìyàn inú àgọ́ mi ,

Ta ni ì ì jẹ ẹran rẹ̀ àjẹyó?

32 Àlejò wọ̀ ni ìgboro ;

èmí ṣí ìlẹ̀kùn mi sílẹ̀ fún èrò.

33 mo ̀ṣẹ̀ mi mọ́lẹ̀ Adamu ni pápá,

̀bi mi pamọ́ ni àyà mi.

34 ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni mo ha bẹ̀?

Tàbí ̀gàn àwọn ìdílé ń ̀?

mo fi pa ẹnu mọ́, èmí fi sọ̀rọ̀ jáde?

35 ("Ìbá ṣe ẹnìkan le gbọ́ ti èmí!

Kíyèsi i, àmì mi, Olódùmarè ó mi lóhùn,

èmí ó ìwé náà olùfisùn mi ti kọ.

36 Nítòótọ́ èmí ìbá gbé le èjìká mi,

èmi ìbá adé mọ́ orí mi.

37 Èmi ìbá sọ iye ìṣísẹ̀ mi fún un,

ọmọ-aládé ni èmi ìbá súnmọ́ ̀dọ̀ rẹ̀.)

38 "ilẹ̀ mi rara lòdì mi

a fi omijé kún gbogbo poro rẹ̀.

39 mo jẹ èso oko mi láìsan owó

tàbí mo ọkàn olúwa rẹ̀ lọ,

40 ̀gún òṣùṣú ó dípò alikama,

àti èpò búburú dípò ọkà barle."

̀rọ̀ Jobu parí.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-