Publicidade

Levítico 18

Ìbálòpọ̀ òfin mu

1 Olúwa sọ fún Mose : 2 "Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli : Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín. 3 gbọdọ̀ ṣe wọ́n ti ń ṣe Ejibiti níbi ti gbé , bẹ́̀ ni gbọdọ̀ ṣe wọ́n ti ń ṣe ilẹ̀ Kenaani níbi èmi ń yín lọ. gbọdọ̀ tẹ̀ìṣe wọn. 4 ̀yin ó máa ṣe òfin mi, ̀yin máa pa ìlànà mi mọ́, láti máa rìn nínú wọn, Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín. 5 18.5: Lk 10.28; Ro 10.5; Ga 3.12. ̀yin ó máa pa ìlànà mi mọ́ àti òfin mi; Ẹni ó ba ṣe, yóò nípa wọn. Èmi ni Olúwa.

6 " Ẹnikẹ́ni nínú yín gbọdọ̀ súnmọ́ ìbátan rẹ̀ láti a lòpọ̀. Èmí ni Olúwa.

7 18.7: Le 20.11. " Ìwọ gbọdọ̀ tàbùkù baba rẹ nípa bíbá ìyá rẹ lòpọ̀, ìyá rẹ̀ ni, ìwọ gbọdọ̀ a lòpọ̀.

8 " Ìwọ gbọdọ̀ tàbùkù baba rẹ nípa bíbá ìyàwó baba rẹ lòpọ̀, nítorí ìhòhò baba rẹ ni.

9 18.9,11: Le 20.17; De 27.22. " Ìwọ gbọdọ̀ arábìnrin rẹ ó jẹ́ ọmọ ìyá rẹ lòpọ̀, yálà a i nílé yín tàbí lóde.

10 " Ìwọ gbọdọ̀ ọmọbìnrin, ọmọ rẹ ọkùnrin lòpọ̀ tàbí ọmọbìnrin ọmọ rẹ obìnrin lòpọ̀ nítorí ìhòhò wọn, ìhòhò ìwọ fúnra rẹ̀ ni.

11 " Ìwọ gbọdọ̀ ọmọbìnrin aya baba rẹ lòpọ̀; èyí a fún baba rẹ nítorí arábìnrin rẹ ni.

12 18.12: Le 20.19. " Ìwọ gbọdọ̀ arábìnrin baba rẹ lòpọ̀ nítorí ìbátan baba rẹ ni.

13 " Ìwọ gbọdọ̀ arábìnrin màmá rẹ lòpọ̀ nítorí ìbátan ìyá rẹ ni.

14 18.14: Le 20.20. " Ìwọ gbọdọ̀ tàbùkù arákùnrin baba rẹ nípa sísún mọ́ aya rẹ̀ láti a lòpọ̀ nítorí ìyàwó ̀gbọ́n baba rẹ ni.

15 18.15: Le 20.12. " Ìwọ gbọdọ̀ ọmọ àna obìnrin rẹ lòpọ̀ nítorí aya ọmọ rẹ ni. ṣe a lòpọ̀.

16 18.16: Le 20.21. " ṣe aya ̀gbọ́n rẹ ọkùnrin lòpọ̀ nítorí yóò tàbùkù ̀gbọ́n rẹ.

17 18.17: Le 20.14. " ṣe ìyá àti ọmọ rẹ obìnrin lòpọ̀, bẹ́̀ ni ìwọ gbọdọ̀ ọmọbìnrin ọmọkùnrin rẹ tàbí ọmọbìnrin ọmọbìnrin rẹ lòpọ̀ nítorí ìbátan rẹ tímọ́tímọ́ ni: nítorí àbùkù ni.

18 " ṣe fẹ́ àbúrò ìyàwó rẹ obìnrin aya gẹ́gẹ́ orogún tàbí a lòpọ̀, nígbà ìyàwó rẹ láààyè.

19 18.19: Le 15.24; 20.18. " ṣe súnmọ́ obìnrin láti a lòpọ̀ nígbà ó ń ṣe nǹkan oṣù, nítorí àkókò àìmọ́ ni.

20 " Ìwọ gbọdọ̀ aya aládùúgbò rẹ lòpọ̀, ìwọ ba à ba ara rẹ jẹ́ pẹ̀rẹ̀.

21 18.21: Le 20.2-5. " Ìwọ gbọdọ̀ fi èyíkéyìí nínú àwọn ọmọ rẹ ẹbọ lórí pẹpẹ òrìṣà Moleki, o tipa bẹ́̀ ba orúkọ Ọlọ́run rẹ jẹ́. Èmi ni Olúwa.

22 18.22: Le 20.13; De 23.18. " Ìwọ gbọdọ̀ ọkùnrin lòpọ̀ ìgbà ènìyàn ń obìnrin lòpọ̀: ìríra ni èyí jẹ́.

23 18.23: Ek 22.19; Le 20.15,16; De 27.21. " Ìwọ gbọdọ̀ ẹranko lòpọ̀ ìwọ ba à ba ara rẹ jẹ́. Obìnrin gbọdọ̀ jọ̀wọ́ ara rẹ̀ sílẹ̀ fún ẹranko láti a lòpọ̀, ohun lòdì ni.

24 " ṣe fi àwọn nǹkan wọ̀nyí ba ara rẹ jẹ́, torí nínú àwọn nǹkan wọ̀nyí ni àwọn orílẹ̀-èdè mo kúrò níwájú yín ti ba ara wọn jẹ́. 25 Nítorí ilẹ̀ náà di àìmọ́ nítorí náà mo fi ìyà jẹ ́ nítorí ̀ṣẹ̀ rẹ̀. Ilẹ̀ náà pọ àwọn olùgbé ibẹ̀ jáde. 26 Ṣùgbọ́n máa pa àṣẹ àti òfin mi mọ́. Onílé tàbí àjèjì ń gbé láàrín yín gbọdọ̀ ṣe ̀kan nínú àwọn ohun ìríra wọ̀nyí. 27 Nítorí gbogbo ohun ìríra wọ̀nyí ni àwọn ènìyàn wọ́n ti gbé ilẹ̀ náà ṣáájú yín ti ṣe ó ilẹ̀ náà di aláìmọ́. 28 sọ ilẹ̀ náà di àìmọ́ yóò pọ̀ yín jáde ó ti pọ àwọn orílẹ̀-èdè ó ti ṣáájú yín jáde.

29 " Ẹnikẹ́ni ó ṣe ohun ìríra wọ̀nyí, irú ẹni náà kúrò láàrín àwọn ènìyàn. 30 Nítorí náà gbọdọ̀ ṣe ohun mo fẹ́, lọ́wọ́ nínú àṣà ìríra wọ̀nyí, wọn ń ṣe . ṣe fi wọ́n ba ara yín jẹ́. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’ "

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-