Publicidade

Levítico 20

Ìjìyà fún ̀ṣẹ̀

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 "Sọ fún àwọn ará Israẹli , Ẹnikẹ́ni nínú àwọn ará Israẹli tàbí àwọn àlejò ń gbé láàrín Israẹli, ó fi èyíkéyìí nínú àwọn ọmọ rẹ̀ fún Moleki, wọ́n pa á, àwọn olùgbé ilẹ̀ náà sọ ́ òkúta pa. 3 Èmi tìkára mi yóò bínú irú ẹni bẹ́̀, ń ó e kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀ fún òrìṣà Moleki ó ti ba ibi mímọ́ mi jẹ́ pẹ̀. 4 àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà mójú kúrò lára irú ẹni bẹ́̀ ó fi ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀ fún òrìṣà Moleki wọn pa irú ẹni bẹ́̀. 5 Èmi yóò bínú irú ẹni bẹ́̀ àti gbogbo ìdílé rẹ̀, èmi yóò wọn kúrò láàrín àwọn ènìyàn wọn, òun àti gbogbo àwọn ó jọ ṣe àgbèrè tọ òrìṣà Moleki lẹ́yìn.

6 " ẹnikẹ́ni tọ àwọn abókùúsọ̀rọ̀ àti àwọn ẹlẹ́mìí òkùnkùn lọ, ó ṣe àgbèrè tọ̀ wọ́n lẹ́yìn, Èmi yóò bínú irú ẹni bẹ́̀, Èmi yóò e kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀.

7 " Torí náà ya ara yín mímọ́ jẹ́ mímọ́, torí , Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín. 8 máa kíyèsi àṣẹ mi, máa pa wọ́n mọ́. Èmi ni Olúwa ó sọ yín di mímọ́.

9 " Ẹnikẹ́ni ó ṣépè baba tàbí ìyá rẹ̀ ni pa, ̀jẹ̀ rẹ̀ lórí ara rẹ̀ torí ó ti ṣépè baba àti ìyá rẹ̀.

10 " ẹnikẹ́ni aya aládùúgbò rẹ̀ lòpọ̀: ọkùnrin àti obìnrin náà ni sọ òkúta pa.

11 " Ẹnikẹ́ni ó aya baba rẹ̀ lòpọ̀ ti tàbùkù baba rẹ̀. Àwọn méjèèjì ni pa. ̀jẹ̀ wọn yóò lórí wọn.

12 " ọkùnrin kan arábìnrin ìyàwó rẹ̀ lòpọ̀, àwọn méjèèjì ni pa, wọ́n ti ṣe ohun ó lòdì, ̀jẹ̀ wọn yóò lórí wọn.

13 " ọkùnrin kan ọkùnrin mìíràn lòpọ̀ wọ́n ti í obìnrin lòpọ̀: àwọn méjèèjì ti ṣe ohun ìríra, pípa ni pa wọ́n, ̀jẹ̀ wọn yóò lórí wọn.

14 " ọkùnrin kan fẹ́ tìyátọmọ papọ̀, ìwà búburú ni èyí: iná ni fi sun wọ́n, òun àti àwọn méjèèjì, ìwà búburú ba à gbilẹ̀ láàrín yín.

15 " ọkùnrin kan ẹranko lòpọ̀, gbọdọ̀ pa ọkùnrin náà àti ẹranko náà.

16 " obìnrin kan súnmọ́ ẹranko ó a lòpọ̀ obìnrin náà àti ẹranko náà ni pa, ̀jẹ̀ wọn yóò lórí ara wọn.

17 " ọkùnrin kan fẹ́ arábìnrin rẹ̀ yálà ọmọbìnrin baba rẹ̀ tàbí ọmọbìnrin ìyá rẹ̀ ó a lòpọ̀, ohun ìtìjú ni èyí, ó wọn kúrò lójú àwọn ènìyàn wọn, ó ti tàbùkù arábìnrin rẹ̀. ̀bi rẹ̀ yóò sórí rẹ̀.

18 " ọkùnrin kan súnmọ́ obìnrin, àkókò nǹkan oṣù rẹ̀ ó a lòpọ̀. Ó ti orísun ̀jẹ̀ rẹ̀. Òun náà gbà á láààyè. Àwọn méjèèjì ni a ó kúrò láàrín àwọn ènìyàn wọn.

19 " ṣe arábìnrin baba tàbí ti ìyá rẹ lòpọ̀, nítorí o ti ìhòhò ìbátan rẹ, ̀yin méjèèjì ni yóò ru ̀bi yín.

20 " ọkùnrin kan aya arákùnrin baba rẹ̀ lòpọ̀ ó ti tàbùkù arákùnrin baba rẹ̀. A ó jẹ wọ́n ìyà; wọn yóò láìlọ́mọ.

21 " ọkùnrin kan gba aya arákùnrin rẹ̀, ohun àìmọ́ ni èyí, ó ti tàbùkù arákùnrin rẹ̀, wọn ó láìlọ́mọ.

22 " pa gbogbo àṣẹ àti òfin mi mọ́, máa ṣe wọ́n. ilẹ̀ náà èmi ó fi fún yín láti máa gbé ba à pọ̀ yín jáde. 23 ṣe tẹ̀àṣà àwọn orílẹ̀-èdè mo jáde níwájú yín torí gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni wọ́n ń ṣe, mo kórìíra wọn. 24 Ṣùgbọ́n mo ti sọ fún yín , "̀yin ni yóò jogún ilẹ̀ wọn, Èmi yóò fi fún yín láti jogún ilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti oyin." Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín ó ti yín sọ́tọ̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn yòókù.

25 " gbọdọ̀ pààlà sáàrín ẹran ó mọ́ àti àwọn mọ́. Láàrín ẹyẹ ó mọ́ àti àwọn mọ́. ṣe sọ ara yín di àìmọ́ nípasẹ̀ àwọn ẹranko tàbí ẹyẹ tàbí ohunkóhun ń rìn lórí ilẹ̀: èyí mo sọ́tọ̀ fún yín gẹ́gẹ́ ohun àìmọ́. 26 gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́ fún mi torí , Èmi Olúwa fẹ́ mímọ́. ti yín kúrò nínú àwọn orílẹ̀-èdè yòókù le jẹ́ tèmi.

27 " Ọkùnrin tàbí obìnrin ó jẹ́ abókùúsọ̀rọ̀ tàbí oṣó láàrín yín ni pa. sọ wọ́n òkúta, ̀jẹ̀ wọn yóò lórí wọn.’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-