Publicidade

Agradecimento

Por Bíblia Online

O agradecimento é a linguagem natural do cristão. Em tudo dai graças! A gratidão a Deus transforma a perspectiva, fortalece a fé e produz alegria em todos os tempos.

Dar graças sempre

Em tudo dai graças, porque esta é a vontade de Deus em Cristo Jesus para convosco. A gratidão é atitude fundamental.

máa dúpẹ́ nígbà gbogbo nínú ipòkípò o ; nítorí , èyí ni ìfẹ́ Ọlọ́run fún yin nínú Kristi Jesu nítòótọ́.

máa dúpẹ́ nígbà gbogbo fún ohun gbogbo lọ́wọ́ Ọlọ́run, àní Baba, orúkọ Jesu Kristi Olúwa .

jẹ́ àlàáfíà Ọlọ́run ó máa ṣe àkóso ọkàn yín, sínú èyí a yín pẹ̀nínú ara kan; máa dúpẹ́. jẹ́ ̀rọ̀ Kristi máa gbé inú yín ̀pọ̀lọpọ̀ nínú ọgbọ́n gbogbo; máa kọ́ , máa gba ara yín níyànjú nínú Saamu, àti orin ìyìn, àti orin ̀, máa kọrin Ọlọ́run ọkàn ọpẹ́. Ohunkóhun ̀yin ń ṣe ̀rọ̀ tàbí ìṣe, máa ṣe gbogbo wọn orúkọ Jesu Olúwa, máa fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run Baba nípasẹ̀ rẹ̀.

jẹ́ àlàáfíà Ọlọ́run ó máa ṣe àkóso ọkàn yín, sínú èyí a yín pẹ̀nínú ara kan; máa dúpẹ́.

jẹ́ ̀rọ̀ Kristi máa gbé inú yín ̀pọ̀lọpọ̀ nínú ọgbọ́n gbogbo; máa kọ́ , máa gba ara yín níyànjú nínú Saamu, àti orin ìyìn, àti orin ̀, máa kọrin Ọlọ́run ọkàn ọpẹ́. Ohunkóhun ̀yin ń ṣe ̀rọ̀ tàbí ìṣe, máa ṣe gbogbo wọn orúkọ Jesu Olúwa, máa fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run Baba nípasẹ̀ rẹ̀.

Àwọn ìlànà fún ìjọ

fi ara yín fún àdúrà gbígbà, ṣọ́ra máa dúpẹ́;

ṣe ṣe àníyàn ohunkóhun; ṣùgbọ́n nínú ohun gbogbo, nípa àdúrà àti ̀bẹ̀ pẹ̀ìdúpẹ́, máa fi ìbéèrè yín hàn fún Ọlọ́run.

Louvor e gratidão

Entrai pelas portas com ação de graças. Rendei graças ao Senhor porque Ele é bom e a sua bondade dura para sempre.

lọ ẹnu-ọ̀rẹ̀ pẹ̀ọpẹ́

àti àgbàlá rẹ̀ pẹ̀ìyìn;

fi ọpẹ́ àti ìyìn fún orúkọ rẹ̀.

fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí ó ṣeun;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí ó ṣeun;

nítorí ìfẹ́ rẹ̀ dúró láéláé.

jẹ́ a iwájú rẹ̀ pẹ̀ọpẹ́

a pòkìkí rẹ̀ pẹ̀ohun èlò

orin àti ìyìn.

Nítorí Olúwa Ọlọ́run títóbi ni,

ọba ó tóbi ju gbogbo òrìṣà lọ.

Saamu. Orin. Fún Ọjọ́ Ìsinmi.

Ohun rere ni láti máa fi ọpẹ́ fún Olúwa

àti láti máa kọrin orúkọ rẹ̀, ̀gá-ògo,

láti kéde ìfẹ́ rẹ̀ òwúrọ̀

àti òtítọ́ rẹ̀ alẹ́,

Ẹni ó ba ẹbọ ọrẹ-ọpẹ́ bu ọlá fún mi; ó tún ̀rẹ̀ ṣe,

èmi ó le fi ìgbàlà Ọlọ́run hàn án."

Ìwọ ni Ọlọ́run mi, èmi yóò máa fi ọpẹ́ fún ;

ìwọ ni Ọlọ́run mi, èmi yóò gbé ga.

fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí ó ṣeun;

nítorí àánú rẹ̀ dúró láéláé.

Nísinsin yìí, Ọlọ́run wa, àwa fi ọpẹ́ fún ,

a fi ìyìn fún orúkọ rẹ̀ ó lógo.

Expressões de gratidão

Graças a Deus pelo seu dom inefável! A gratidão se expressa em oração, louvor e generosidade para com os outros.

Ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run nítorí aláìlèfẹnusọ ̀bùn rẹ̀!

Bẹ́̀ ni a ó sọ yín di ọlọ́rọ̀ nínú ohun gbogbo, fún ìlawọ́ yín gbogbo ń ṣiṣẹ́ ọpẹ́ Ọlọ́run nípa wa.

Ṣùgbọ́n ọpẹ́ fún Ọlọ́run ẹni ó ìṣẹ́gun fún nípa Olúwa Jesu Kristi!

Ìdúpẹ́

Nígbà gbogbo ni mo ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run fún oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ fi fún un yín nínú Kristi Jesu.

Ìfojúsọ́Paulu láti bẹ Romu

àkọ́kọ́, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run nípasẹ̀ Jesu Kristi fún gbogbo yín, nítorí a ń ròyìn ìgbàgbọ́ yin káàkiri gbogbo ayé.

Lóòótọ́, wọn òye nípa Ọlọ́run dáradára, ṣùgbọ́n wọn yìn ín lógo Ọlọ́run, wọ́n dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀; wọ́n ń ro èrò asán, ọkàn aṣiwèrè wọn ṣókùnkùn.

Nítorí láti ̀dọ̀ rẹ̀, àti nípa rẹ̀, àti fún un ni ohun gbogbo;

ẹni ògo fún láéláé! Àmín.

" ‘ "Olúwa bùkún un yín,

ó pa yín mọ́.

Olúwa o ojú rẹ̀ ó mọ́lẹ̀ i yín lára.

ó ṣàánú fún un yín.

Olúwa bojú yín,

ó fún un yín àlàáfíà." 

Ṣùgbọ́n èmi yóò fi orin ọpẹ́, ẹbọ .

Èmi yóò san ̀jẹ́ mo ti jẹ́.

Ìgbàlà láti ̀dọ̀ Olúwa.’ "

Ìdúpẹ́ àti àdúrà

Ó yẹ a máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run nígbà gbogbo nítorí yín, ará, àní gẹ́gẹ́ ó ti yẹ, nítorí ìgbàgbọ́ yín ń dàgbà gidigidi, àti ìfẹ́ olúkúlùkù yín ara yín ń di púpọ̀.

Ìdúpẹ́

Mo ọpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run, ẹni èmi ń sìn pẹ̀̀ọkàn mímọ́ gẹ́gẹ́ àwọn baba mi ti í ṣe, ni àìsimi lọ́sàn án àti lóru ni mo ń ṣe ìrántí rẹ nínú àdúrà mi.

Èmi sinmi láti máa dúpẹ́ nítorí yín, àti láti máa rántí yín nínú àdúrà mi.

Nítorí náà àwa ń gbà ilẹ̀ ọba ti a , jẹ́ a ọpẹ́ nípa èyí ti a fi máa sin Ọlọ́run ni ìtẹ́wọ́gbà pẹ̀̀wọ̀ àti ìbẹ̀rẹ̀.

ibi gbogbo àti ̀gbogbo, Feliksi ọlọ́jùlọ, àwa ń tẹ́wọ́gbà á pẹ̀ọpẹ́ gbogbo.

Nígbà ó wọn, ó fún wọn , "lọ í fi ara yín hàn fún àwọn àlùfáà." Ó ṣe, wọ́n ti ń lọ, wọ́n di mímọ́.

Nígbà ̀kan nínú wọn i a òun láradá ó padà, ó fi ohùn rara yin Ọlọ́run lógo. Ó wólẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ̀, ó ń dúpẹ́ ọwọ́ rẹ̀: ará Samaria ni òun í ṣe.

Jesu dáhùn , "Àwọn mẹ́wàá a sọ di mímọ́? Àwọn mẹ́sàn-án ìyókù ha ? A ẹnìkan ó padà fi ògo fún Ọlọ́run, ṣe àlejò yìí?" Ó fún un , "Dìde, o máa lọ, ìgbàgbọ́ rẹ láradá."

ó ti ń wọ inú ìletò kan lọ, àwọn ọkùnrin adẹ́tẹ̀ mẹ́wàá pàdé rẹ̀, wọ́n dúró òkèrè, wọ́n kígbe sókè , "Jesu, Olùkọ́, ṣàánú fún wa."

Nígbà ó wọn, ó fún wọn , "lọ í fi ara yín hàn fún àwọn àlùfáà." Ó ṣe, wọ́n ti ń lọ, wọ́n di mímọ́.

Nígbà ̀kan nínú wọn i a òun láradá ó padà, ó fi ohùn rara yin Ọlọ́run lógo. Ó wólẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ̀, ó ń dúpẹ́ ọwọ́ rẹ̀: ará Samaria ni òun í ṣe.

Jesu dáhùn , "Àwọn mẹ́wàá a sọ di mímọ́? Àwọn mẹ́sàn-án ìyókù ha ? A ẹnìkan ó padà fi ògo fún Ọlọ́run, ṣe àlejò yìí?" Ó fún un , "Dìde, o máa lọ, ìgbàgbọ́ rẹ láradá."

Ìdúpẹ́ àti àdúrà

Mo ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run mi gbogbo ìgbà mo rántí yín.

Seja o primeiro
Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-