Publicidade

Salmos 107

1 fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí ó ṣeun;

nítorí ìfẹ́ rẹ̀ dúró láéláé.

2 Jẹ́ àwọn ẹni ìràpadà Olúwa ó báyìí,

àwọn ẹni ó padà kúrò lọ́wọ́ ̀,

3 àwọn ó kójọ láti ilẹ̀ wọ̀n-ọn-nì,

láti ìlà-oòrùn àti ìwọ̀-oòrùn,

láti àríwá àti Òkun .

4 Wọ́n ń rìn káàkiri aginjù ibi ̀,

wọn ̀lọ ìlú níbi

wọn ó máa gbé.

5 Ebi ń pa wọn, òǹgbẹ gbẹ wọ́n,

ó rẹ ọkàn wọn nínú wọn.

6 ìgbà náà, wọ́n kígbe sókè

Olúwa nínú ìdààmú wọn,

ó yọ wọ́n kúrò nínú ìrora wọn

7 Ó fi ̀títọ́ hàn wọ́n ìlú

wọn máa gbé.

8 jẹ́ wọn máa yin Olúwa nítorí ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti nítorí iṣẹ́

ìyanu rẹ̀ àwọn ọmọ ènìyàn,

9 nítorí ó tẹ́ ìfẹ́ ọkàn lọ́run

ó fi ìre fún ọkàn ebi ń pa.

10 ̀pọ̀ jókòó nínú òkùnkùn àti òjìji ikú,

a wọ́n ìrora àti irin,

11 nítorí wọ́n ṣe àìgbọ́ràn ̀rọ̀

Ọlọ́run, wọ́n kẹ́gàn ìbáwí ̀gá-ògo,

12 Ó fi ìkorò rẹ àyà wọn sílẹ̀;

wọn ṣubú, ṣí ẹni

yóò ràn wọ́n lọ́wọ́.

13 ìgbà náà wọ́n pe

Olúwa nínú ìdààmú wọn,

ó gbà wọ́n nínú ìṣòro wọn

14 Ó wọn jáde kúrò nínú

òkùnkùn àti òjìji ikú,

ó fa irin wọ́n fi wọ́n .

15 jẹ́ wọn fi ọpẹ́ fún Olúwa! Nítorí ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti nítorí iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ ọmọ ènìyàn.

16 Nítorí ó ìlẹ̀kùn idẹ wọ̀n-ọn-nì

ó irin wọn agbede-méjì.

17 ̀pọ̀ di aṣiwèrè nítorí ìrékọjá wọn

wọ́n pọ́n wọn lójú nítorí ̀ṣẹ̀ wọn.

18 Wọ́n kọ gbogbo oúnjẹ

wọ́n súnmọ́ ẹnu-ọ̀ikú.

19 Nígbà náà wọ́n kígbe Olúwa nínú ìṣòro wọn,

ó yọ wọ́n nínú ìdààmú wọn.

20 Ó rán ̀rọ̀ rẹ̀, ara wọn

ó yọ wọ́n nínú isà òkú.

21 jẹ́ wọ́n fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ fún ọmọ ènìyàn.

22 Jẹ́ wọn ẹbọ ọpẹ́

wọn ó fi ayọ̀ sọ̀rọ̀ iṣẹ́ rẹ̀.

23 Àwọn ń sọ̀kalẹ̀ lọ Òkun nínú ọkọ̀ ojú omi,

wọ́n jẹ́ oníṣòwò nínú omi ńlá.

24 Wọ́n iṣẹ́ Olúwa,

àti iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ nínú ibú.

25 Nítorí ó pàṣẹ, ó ìjì fẹ́

ó gbé ríru rẹ̀ sókè.

26 Wọ́n gòkè lọ ̀run wọ́n

tún sọ̀kalẹ̀ lọ ibú:

nítorí ìpọ́njú, ọkàn wọn di omi.

27 Wọ́n ń ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n ̀mùtí ènìyàn:

ọgbọ́n wọn òpin.

28 Nígbà náà wọ́n ń kígbe sókè

Olúwa nínú ìdààmú wọn,

ó wọn jáde nínú ìṣòro wọn.

29 Ó sọ ìjì di ìdákẹ́rọ́rọ́

bẹ́̀ ni ríru omi rẹ̀ dúró jẹ́́.

30 Inú wọn dùn nígbà ara wọn balẹ̀,

ó wọn lọ ibi ọkàn wọn lọ.

31 Jẹ́ wọn fi ọpẹ́ fún

Olúwa nítorí ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀

àti iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ fún ọmọ ènìyàn.

32 Jẹ́ wọn gbé e ga àárín àwọn ènìyàn

wọn ó yìn ín ìjọ àwọn àgbàgbà.

33 Ó sọ odò di aginjù,

àti orísun omi di ilẹ̀ gbígbẹ.

34 Ilẹ̀ eléso di aṣálẹ̀

nítorí ìwà búburú àwọn ó nínú rẹ̀.

35 O sọ aginjù di adágún omi àti

ilẹ̀ gbígbẹ di orísun omi,

36 níbẹ̀ ó ẹni ebi ń pa ,

wọ́n pilẹ̀ ibi wọn ó máa gbé.

37 Wọn fún irúgbìn, wọ́n gbin ọgbà àjàrà

yóò máa so èso ó dára;

38 Ó bùkún wọn, wọ́n pọ̀ i iye

jẹ́ ẹran ̀sìn wọn ó dínkù.

39 Nígbà náà, ọjọ́ wọn kúrú,

ìnira, ìpọ́njú àti ìṣòro wọn dínkù,

40 ẹni ó da ̀gàn lu ọmọ-aládé

ó wọn rìn níbi ̀.

41 Ṣùgbọ́n ó gbé aláìní sókè kúrò nínú ìnira

ó ìdílé wọn pọ̀ agbo ẹran.

42 Àwọn ó dúró i, inú wọn dùn

ṣùgbọ́n gbogbo olùṣe búburú yóò pa ẹnu rẹ̀ mọ́.

43 Ẹni ó gbọ́n, jẹ́ ó kíyèsi nǹkan wọ̀nyí

ó wo títóbi ìfẹ́ Olúwa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-