Publicidade

Salmos 92

Saamu. Orin. Fún Ọjọ́ Ìsinmi.

1 Ohun rere ni láti máa fi ọpẹ́ fún Olúwa

àti láti máa kọrin orúkọ rẹ̀, ̀gá-ògo,

2 láti kéde ìfẹ́ rẹ̀ òwúrọ̀

àti òtítọ́ rẹ̀ alẹ́,

3 lára ohùn èlò orin olókùn mẹ́wàá

àti lára ohun èlò orin haapu.

4 Nítorí ìwọ ni ó inú mi dùn

nípa iṣẹ́ rẹ Olúwa;

èmi kọrin ayọ̀ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.

5 Báwo ni iṣẹ́ rẹ tóbi , Olúwa?

Èrò inú rẹ ìjìnlẹ̀ ni!

6 Òpè ènìyàn mọ̀ ́n,

aṣiwèrè mọ̀ ́n,

7 nígbà àwọn ènìyàn búburú jáde i koríko

àti gbogbo àwọn olùṣe búburú gbèrú,

wọn yóò run láéláé.

8 Ṣùgbọ́n ìwọ Olúwa ni a ó gbéga títí láé.

9 Nítorí nítòótọ́ àwọn ̀rẹ,

Olúwa,

nítòótọ́ àwọn ̀rẹ yóò ṣègbé;

gbogbo àwọn olùṣe búburú

ni a ó fọ́nká.

10 Ìwọ ti gbé ìwo mi ga i ti màlúù igbó;

òróró dídára ni a mi orí.

11 Ojú mi ti ìṣubú àwọn ̀mi;

ìparun àwọn ènìyàn búburú

ó dìde mi.

12 Olódodo yóò gbèrú i igi ̀pẹ,

wọn yóò dàgbà i igi kedari Lebanoni,

13 a gbìn ilé Olúwa,

Wọn yóò rúwé nínú àgbàlá Ọlọ́run wa.

14 Wọn yóò máa so èso ìgbà ogbó,

wọn yóò dúró àkọ̀tun, wọn yóò tutù nini,

15 láti fihàn , "Ẹni ìdúró ṣinṣin ni Olúwa;

òun ni àpáta mi, ṣí aburú

kankan nínú rẹ̀."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-