Publicidade

Arca da aliança

Por Bíblia Online

A Arca da Aliança era o símbolo mais sagrado de Israel — representava a presença de Deus no meio do seu povo. Sobre ela brilhava a glória do Senhor entre os querubins.

Àpótí ̀

"Wọn yóò fi igi ṣittimu ṣe àpótí, ìgbọ̀nwọ́ méjì ààbọ̀ ni gígùn rẹ̀, ìgbọ̀nwọ́ kan ààbọ̀ ni fífẹ̀ rẹ̀, ìgbọ̀nwọ́ kan ààbọ̀ ni gíga rẹ̀. Ìwọ ó fi ojúlówó wúrà, ó inú àti òde, ìwọ ó fi wúrà gbá etí rẹ̀ yíká. Ìwọ ó da òrùka wúrà mẹ́rin fún. Ìwọ ó fi wọ́n igun mẹ́rẹ̀̀rin ẹsẹ̀ rẹ̀, òrùka wúrà méjì yóò ̀gbẹ́ kìn-ín-ní, òrùka wúrà méjì yóò ẹgbẹ́ kejì. Ìwọ ó fi igi kasia ṣe ̀mẹ́rin, ìwọ ó fi wúrà wọ́n. Ìwọ ó fi ̀náà bọ òrùka ̀gbẹ́ kọ̀̀kan àpótí ̀náà láti fi gbé e. Òpó náà yóò nínú òrùka lára àpótí ̀; a yọ wọ́n kúrò. Nígbà náà ni ìwọ yóò fi ̀ti èmi yóò fi fún sínú àpótí náà.

"Ìwọ ó fi ojúlówó wúrà ṣe ìtẹ́ àánú; ìgbọ̀nwọ́ méjì àti ààbọ̀ gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ kan àti ààbọ̀ fífẹ̀. Ìwọ ó ṣe kérúbù méjì láti inú wúrà a fi òòlù igun ìtẹ́ àánú náà. Ìwọ ó ṣe kérúbù kan igun kìn-ín-ní àti kérúbù kejì igun kejì, kérúbù náà jẹ́ irú kan náà igun méjèèjì pẹ̀ìbòrí wọn. Àwọn kérúbù na ìyẹ́ apá wọn sókè, wọn yóò fi ìyẹ́ apá wọn ṣe ibòòji orí ìtẹ́ àánú. Àwọn kérúbù náà yóò kọ ojú ara wọn, wọn yóò máa wo ̀kánkán ìtẹ́. Gbé ọmọrí orí àpótí ̀o fi ̀èyí èmí yóò fi fún sínú àpótí ̀.

Níbẹ̀, ni òkè ìtẹ́, àárín kérúbù méjèèjì ti ó ni orí àpótí ̀ni èmi yóò ti pàdé rẹ, ti èmi yóò fún àwọn òfin mi fún àwọn ọmọ Israẹli.

Àpótí náà

Besaleli fi igi ṣittimu ṣe àpótí náà, ìgbọ̀nwọ́ méjì ààbọ̀ ni gígùn rẹ̀, ìgbọ̀nwọ́ kan ààbọ̀ ni fífẹ̀ rẹ̀, ìgbọ̀nwọ́ kan ààbọ̀ ni gíga rẹ̀.

Gbígbé àgọ́

Olúwa fún Mose , "ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kìn-ín-ní ni ó gbé àgọ́ náà, àgọ́ àjọ náà . Gbé àpótí ̀inú rẹ̀, ó bo àpótí náà pẹ̀aṣọ títa.

Ó mu ̀, ó fi sínú àpótí, ó so àwọn òpó mọ́ àpótí náà, ó fi àánú bo orí rẹ. Ó gbé àpótí náà sínú àgọ́; ó sọ aṣọ títa, ó ta á bo àpótí ̀, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

Nígbà Mose wọ inú àgọ́ ìpàdé láti Olúwa sọ̀rọ̀, Olúwa sọ̀rọ̀ i láti àárín àwọn kérúbù méjì láti orí ìtẹ́ àánú ó bo àpótí ̀, ohùn náà Mose sọ̀rọ̀.

Wọ́n gbéra láti orí òkè Olúwa ìrìn ọjọ́ mẹ́ta. Àpótí ̀Olúwa ń lọ níwájú wọn fún gbogbo ọjọ́ mẹ́ta yìí láti ibi ìsinmi fún wọn. Ìkùùkuu Olúwa lórí wọn lọ́sàn nígbà wọ́n gbéra kúrò ibùdó.

Nígbàkígbà àpótí ̀gbéra Mose yóò ,

"Dìde, Olúwa!

a àwọn ̀rẹ ,

àwọn ó kórìíra rẹ sálọ níwájú rẹ."

Nígbàkígbà àpótí ̀sinmi yóò ,

"Padà, Olúwa,

sọ́dọ̀ àwọn àìmoye ẹgbẹẹgbẹ̀rún Israẹli."

̀Aaroni rúwé

Olúwa sọ fún Mose , "Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli o gba ̀méjìlá lọ́wọ́ wọn, ̀kọ̀̀kan lọ́wọ́ olórí ìdílé ̀ìran wọn, kọ orúkọ ènìyàn kọ̀̀kan ara ̀rẹ̀. Lórí ̀Lefi kọ orúkọ Aaroni, nítorí ̀kọ̀̀kan gbọdọ̀ fún olórí ìdílé kọ̀̀kan yóò jẹ́ orí fún ̀ìran kọ̀̀kan. wọn àgọ́ ìpàdé níwájú ̀níbi èmi ti ń pàdé yín. ̀ó jẹ́ ti ẹni èmi yàn yóò rúwé, èmi yóò kíkùn gbogbo ìgbà àwọn ọmọ Israẹli yín dúró."

Nígbà náà Mose àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀, àwọn olórí wọn fún un ̀méjìlá, ̀kan fún olórí kọ̀̀kan ̀ìran wọn, ̀Aaroni lára àwọn ̀náà. Mose fi ̀wọ̀nyí lélẹ̀ níwájú Olúwa nínú àgọ́ ̀.

Ó ṣe ọjọ́ kejì Mose wọ inú àgọ́ ̀lọ, ó ̀Aaroni, ó dúró fún ̀Lefi, í ṣe ó nìkan, ṣùgbọ́n ó rúwé, ó yọ ìtànná, ó so èso almondi. Nígbà náà ni Mose gbogbo àwọn ̀jáde láti iwájú Olúwa fún àwọn ọmọ Israẹli. Wọ́n wọ́n, ẹnìkọ̀̀kan ̀tirẹ̀.

Olúwa sọ fún Mose , "̀Aaroni padà síwájú ̀, láti fi pamọ́ gẹ́gẹ́ àmì fún àwọn ọlọ̀tẹ̀. Èyí ó òpin kíkùn sínú wọn mi, wọn ó ba à ." Mose ṣe gẹ́gẹ́ Olúwa ti páláṣẹ fún un.

Nígbà àwọn ènìyàn gbéra láti ibùdó láti kọjá nínú odò Jordani, àwọn àlùfáà ó ru àpótí ̀náà ń lọ níwájú wọn. Odò Jordani máa ń kíkún gbogbo ìgbà ìkórè. Ṣùgbọ́n àwọn àlùfáà ó ru àpótí ̀ti odò Jordani ẹsẹ̀ wọn kan etí omi, omi ń ti òkè sàn dúró. Ó gbá jọ òkìtì òkèèrè, ìlú a ń Adamu, ó tòsí Saretani; nígbà omi ń sàn lọ sínú Òkun aginjù (ti o túmọ̀ Òkun Iyọ̀) kúrò pátápátá. Bẹ́̀ ni àwọn ènìyàn kọjá òdìkejì ìdojúkọ Jeriko. Àwọn àlùfáà ó ru àpótí ̀Olúwa dúró ṣinṣin lórí ilẹ̀ gbígbẹ àárín Jordani, nígbà gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ń kọjá títí gbogbo orílẹ̀-èdè náà fi rékọjá nínú odò Jordani lórí ilẹ̀ gbígbẹ.

Àwọn àlùfáà náà jáde láti inú odò pẹ̀àpótí ̀Olúwa ni orí wọn. wọ́n ti fi ẹsẹ̀ wọn tẹ orí ilẹ̀ gbígbẹ ni omi Jordani náà padà ààyè e rẹ̀, o kún wọ bèbè i ti àtẹ̀yìnwá.

Wàyí o, a ti Jeriko mọ́gágá nítorí àwọn ọmọ Israẹli, ẹnikẹ́ni jáde, ẹnikẹ́ni wọlé.

Nígbà náà ni Olúwa fún Joṣua , "ó, mo ti fi Jeriko lọ́wọ́ pẹ̀ọba rẹ̀ àti àwọn jagunjagun rẹ̀. wọ́de ogun ìlú náà lẹ́̀kan pẹ̀gbogbo àwọn jagunjagun. ṣe èyí fún ọjọ́ mẹ́. Jẹ́ àwọn àlùfáà méje gbé fèrè ìwo àgbò iwájú àpótí ̀. ọjọ́ keje, wọ́de ogun ìlú náà ìgbà méje, pẹ̀àwọn àlùfáà ń fọn fèrè. Nígbà gbọ́ ohùn fèrè náà, àwọn ènìyàn yèè igbe ńlá, nígbà náà ni odi ìlú náà yóò lulẹ̀, àwọn ènìyàn yóò lọ òkè, olúkúlùkù yóò wọ inú rẹ̀ lọ tààrà."

Bẹ́̀ ni Joṣua ọmọ Nuni pe àwọn àlùfáà ó fún wọn , "gbé àpótí ̀Olúwa náà àwọn àlùfáà méje ó ru fèrè ìwo iwájú u rẹ̀." Ó pàṣẹ fún àwọn ènìyàn náà , "lọ, ìlú náà pẹ̀àwọn olùṣọ́ ó hámọ́ra kọjá iwájú àpótí ̀Olúwa."

Nígbà àwọn àlùfáà fọn ìpè, àwọn ènìyàn náà . Ó ṣe, àwọn ènìyàn ti gbọ́ ìró ìpè, àwọn ènìyàn ìhó ńlá, odi ìlú náà lulẹ̀ bẹẹrẹ; bẹ́̀ ni olúkúlùkù ya wọ inú ìlú náà lọ tààrà, wọ́n ìlú náà.

Àwọn Filistini ogun wọn sọ̀kalẹ̀ láti pàdé Israẹli, nígbà ogun náà bẹ̀rẹ̀, àwọn Filistini ṣẹ́gun Israẹli wọ́n pa ẹgbàajì (4,000) ọkùnrin nínú ogun náà. Nígbà àwọn ọmọ-ogun náà padà ibùdó, àwọn àgbàgbà Israẹli béèrè , "Èéṣe ti Olúwa fi àwọn Filistini ṣẹ́gun wa lónìí? jẹ́ a gbé àpótí ̀Olúwa láti Ṣilo , ó ba à le lọ pẹ̀wa ó gbà kúrò lọ́wọ́ àwọn ̀wa."

Nítorí náà a rán àwọn ènìyàn lọ Ṣilo, wọ́n gbé àpótí ̀Olúwa àwọn ọmọ-ogun , ẹni ń láàrín àwọn Kérúbù àti àwọn ọmọ Eli méjèèjì Hofini àti Finehasi níbẹ̀ pẹ̀àpótí ̀Ọlọ́run.

Nígbà àpótí ̀Olúwa ibùdó, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli dìde láti kígbe bẹ́̀ ilẹ̀ tìtì. ìgbà àwọn Filistini gbọ́ ariwo náà wọ́n béèrè , "ni gbogbo ariwo yìí ibùdó Heberu?"

Nígbà wọ́n mọ̀ àpótí ̀Olúwa ti ibùdó, àwọn Filistini bẹ̀, Ọlọ́run kékeré ti wọ ibùdó, wọ́n , "A wọ wàhálà, irú èyí ì ṣẹlẹ̀ . Àwa gbé! Ta ni yóò gbà kúrò lọ́wọ́ Ọlọ́run alágbára yìí? Àwọn ni Ọlọ́run ó fi ìpọ́njú pa àwọn ará Ejibiti pẹ̀gbogbo àjàkálẹ̀-ààrùn aginjù. jẹ́ alágbára Filistini, ṣe ọkùnrin, bẹ́̀ kọ́, ̀yin yóò di ẹrú àwọn Heberu, wọ́n ti jẹ́ i yín. jẹ́ alágbára ọkùnrin, jagun!"

Nígbà náà àwọn Filistini , wọ́n ṣẹ́gun àwọn Israẹli olúkúlùkù padà sínú àgọ́ rẹ̀, wọ́n pa ̀pọ̀ ènìyàn, àwọn ará Israẹli ó ogun jẹ́ ẹgbàá mẹ́̀́dógún (30,000) àwọn ọmọ-ogun orí ilẹ̀. Wọ́n gba àpótí ̀Olúwa, àwọn ọmọkùnrin Eli méjèèjì , Hofini àti Finehasi.

Ọwọ́ Olúwa wúwo lára àwọn ènìyàn Aṣdodu àti gbogbo agbègbè rẹ̀: ó ìparun sórí wọn, ó pọ́n wọn lójú pẹ̀ààrùn oníkókó. Nígbà àwọn ọkùnrin Aṣdodu ohun ó ṣẹlẹ̀, wọ́n , "Àpótí ̀Ọlọ́run ti Israẹli gbọdọ̀ dúró níbí yìí pẹ̀wa, nítorí ọwọ́ rẹ̀ wúwo lára wa àti lára Dagoni ọlọ́run ." Nígbà náà ni wọ́n gbogbo àwọn olórí Filistini jọ wọ́n bi wọ́n , "ni a ó ṣe pẹ̀àpótí ̀Ọlọ́run àwọn Israẹli?"

Wọ́n dáhùn , "jẹ́ á gbé àpótí ̀Ọlọ́run àwọn Israẹli lọ Gati." Wọ́n gbé àpótí ̀Ọlọ́run Israẹli.

Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà wọ́n ti gbé e, ọwọ́ Olúwa ìlú náà, ó jìnnìjìnnì wọn. Ó pọ́n àwọn ènìyàn ìlú náà lójú, ọmọdé àti àgbà, pẹ̀àjàkálẹ̀-ààrùn oníkókó. Wọ́n gbé àpótí ̀Ọlọ́run lọ Ekroni.

àpótí ̀Ọlọ́run ṣe wọ Ekroni, àwọn ará Ekroni fi igbe ta , "Wọ́n ti gbé àpótí ̀Ọlọ́run Israẹli tọ̀ láti pa àti àwọn ènìyàn wa." Nígbà náà ni wọ́n pe gbogbo àwọn olórí àwọn Filistini jọ wọ́n , "gbé àpótí ̀Ọlọ́run àwọn Israẹli lọ: jẹ́ ó padà ààyè rẹ̀, bẹ́̀ kọ́ yóò pa àti àwọn ènìyàn wa." Ikú ti jìnnìjìnnì àwọn ará ìlú, ọwọ́ Ọlọ́run wúwo lára wọn.

Àpótí ̀Olúwa padà Israẹli

Nígbà àpótí ̀Olúwa ti agbègbè Filistini fún oṣù méje, àwọn ará Filistini pe àwọn àlùfáà, àti àwọn alásọtẹ́lẹ̀, wọ́n sọ , "ni a ṣe pẹ̀àpótí ̀Olúwa? Sọ fún wa àwa yóò ti a padà ààyè rẹ̀."

Wọ́n dáhùn , "àpótí ̀Ọlọ́run ti àwọn ọmọ Israẹli padà, ṣe a padà òfìfo, ṣùgbọ́n ó ti ó , fún un ẹbọ ̀bi. Nígbà náà ni a ó un yín láradá, ̀yin yóò mọ ìdí ọwọ́ rẹ̀ fi ì kúrò lára yín."

Nígbà náà ni wọ́n ṣe èyí. Wọ́n abo màlúù méjì, ń fi ọmú fún ọmọ, wọn mọ́ ara, wọ́n é ni ilé kẹ̀kẹ́ ẹrù, wọn so àwọn ọmọ wọn mọ́lẹ̀ ni ilé. Wọ́n gbé àpótí ̀Olúwa orí kẹ̀kẹ́ ̀gbẹ́ rẹ̀ ni àpótí eku ̀lírí wúrà àti àwòrán ààrùn oníkókó níbẹ̀. Nígbà náà; àwọn màlúù lọ tààrà ìhà Beti-Ṣemeṣi, wọ́n ń lọ tààrà, wọ́n ń dún wọ́n ti ń lọ. Wọn ̀tún tàbí òsì. Àwọn aláṣẹ Filistini tẹ̀wọn títí ibodè Beti-Ṣemeṣi.

Nísinsin yìí, àwọn ará Beti-Ṣemeṣi ń kórè jéró wọn pẹ̀tẹ́lẹ̀, nígbà wọ́n wo òkè wọ́n àpótí ̀Olúwa, wọ́n yọ̀ níwájú rẹ̀. Kẹ̀kẹ́ ẹrù pápá Joṣua ti Beti-Ṣemeṣi, níbẹ̀ ni ó ti dúró ̀àpáta ńlá kan. Àwọn ènìyàn igi ara kẹ̀kẹ́ ẹrù wẹ́wẹ́ wọ́n fi àwọn màlúù náà ẹbọ sísun Olúwa. Àwọn ará Lefi gbé àpótí ̀Olúwa ìsàlẹ̀ pẹ̀àpótí ohun èlò wúrà níbẹ̀, wọ́n gbé wọn ka orí àpáta ńlá náà. ọjọ́ náà, àwọn ará Beti-Ṣemeṣi ẹbọ sísun, wọ́n ṣe ìrúbọ Olúwa.

Nígbà náà àwọn ará Kiriati-Jearimu , wọ́n gbé àpótí ̀Olúwa. Wọ́n gbé e lọ ilé Abinadabu lórí òkè, wọ́n ya Eleasari ọmọ rẹ̀ mímọ́ láti ṣọ́ àpótí ̀Olúwa.

Samuẹli ṣẹ́gun àwọn ará Filistini Mispa

Ó jẹ́ ìgbà pípẹ́, ogún ọdún ni àpótí ̀Olúwa fi Kiriati-Jearimu. Gbogbo ilé Israẹli ṣọ̀fọ̀ wọ́n pohùnréré ẹkún Olúwa.

A fún Dafidi ọba , "Olúwa ti bùkún fún ilé Obedi-Edomu, àti gbogbo èyí í ṣe tirẹ̀, nítorí àpótí ̀Ọlọ́run." Dafidi lọ, ó àpótí ̀náà gòkè láti ilé Obedi-Edomu ìlú Dafidi pẹ̀ayọ̀. Ó ṣe nígbà àwọn ènìyàn ó ru àpótí ̀Olúwa ṣí ẹsẹ̀ mẹ́, òun a fi màlúù àti ẹran àbọ́pa ẹbọ. Dafidi fi gbogbo agbára rẹ̀ níwájú Olúwa; Dafidi wọ efodu ̀gbọ̀. Bẹ́̀ ni Dafidi àti gbogbo ilé Israẹli gbé àpótí ̀Olúwa gòkè , pẹ̀ìhó ayọ̀, àti pẹ̀ìró ìpè.

A gbé àpótí ̀inú tẹmpili

Nígbà náà ni Solomoni pe àwọn àgbàgbà Israẹli àti gbogbo àwọn olórí àwọn ̀àti àwọn olórí ìdílé àwọn ọmọ Israẹli jọ papọ̀, níwájú Solomoni ọba Jerusalẹmu, láti gbé àpótí ̀Olúwa láti ìlú Dafidi, ń ṣe Sioni. Gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli pe ara wọn jọ sọ́dọ̀ Solomoni ọba àkókò àjọ ọdún oṣù Etanimu í ṣe oṣù keje.

Nígbà gbogbo àwọn àgbàgbà Israẹli , àwọn àlùfáà gbé àpótí ̀, wọ́n gbé àpótí ̀Olúwa àti àgọ́ àjọ ènìyàn àti gbogbo ohun èlò mímọ́ ó nínú àgọ́. Àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi gbé wọn gòkè , àti Solomoni ọba, àti gbogbo ìjọ ènìyàn ó péjọ ̀dọ̀ rẹ̀ pẹ̀rẹ̀ níwájú àpótí ̀, wọ́n ń fi ̀pọ̀lọpọ̀ àgùntàn àti màlúù a le mọ iye, àti a le ẹbọ.

Nígbà náà ni àwọn àlùfáà gbé àpótí ̀ti májẹ̀Olúwa ipò rẹ̀, ibi inú lọ́hùn ún ilé Olúwa, Ibi Mímọ́ Jùlọ, wọ́n gbé e abẹ́ ìyẹ́ àwọn kérúbù. Àwọn kérúbù na ìyẹ́ wọn méjèèjì ibi àpótí ̀, wọ́n bo àpótí ̀náà, àti àwọn ̀rẹ̀ a fi ń gbé e. Àwọn ̀yìí ga bẹ́̀ a fi le orí wọn láti Ibi Mímọ́ níwájú ibi a mímọ́, ṣùgbọ́n a wọn lóde Ibi Mímọ́, wọ́n níbẹ̀ títí di òní yìí. ohun kankan nínú àpótí ̀ṣe wàláà òkúta méjì Mose ti fi ibẹ̀ Horebu, níbi Olúwa ti àwọn ọmọ Israẹli májẹ̀, lẹ́yìn ìgbà wọ́n jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti.

Nígbà àwọn àlùfáà jáde láti Ibi Mímọ́, àwọsánmọ̀ kún ilé Olúwa. Àwọn àlùfáà le ṣiṣẹ́ wọn nítorí àwọsánmọ̀ náà, nítorí ògo Olúwa kún ilé náà.

"Padà, ̀yin ènìyàn aláìnígbàgbọ́," ni Olúwa , "nítorí èmi ni ọkọ rẹ. Èmi ó yàn ́, ̀kan láti ìlú àti méjì láti ̀. Èmi ó Sioni. Lẹ́yìn èyí, èmi ó fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn láti inú ọkàn mi, wọn yóò ṣáájú yín pẹ̀òye àti ìmọ̀. ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, ̀yin pọ̀ i lórí ilẹ̀ náà," ni Olúwa , "àwọn ènìyàn tún sọ , Àpótí ̀Olúwa.ìrántí wọn mọ́, a yóò pàdánù rẹ̀, bẹ́̀ ni a yóò tún kan òmíràn mọ́.

Ìsìn nínú àgọ́ ayé yìí

Bẹ́̀ ni májẹ̀àkọ́kọ́ ìlànà fún ìsìn àti ibi mímọ́ ti ayé yìí. A gbé àgọ́ kan dìde. Nínú yàrá rẹ̀ àkọ́kọ́ ni a ti ̀fìtílà, tábìlì, àti àkàrà ìfihàn. Èyí a ń ibi mímọ́. Àti lẹ́yìn aṣọ ìkélé kejì, òun ni àgọ́ à ń Ibi Mímọ́ Jùlọ; ó àwo tùràrí wúrà, àti àpótí ̀a fi wúrà yíká, nínú èyí ìkòkò wúrà ó manna gbé , àti ̀Aaroni o rúdí, àti àwọn wàláà májẹ̀; àti lórí àpótí ni àwọn kérúbù ògo ti i síji bo ìtẹ́ àánú; èyí a sọ̀rọ̀ rẹ̀ nísinsin yìí lọ́kọ̀̀kan.

A ṣí tẹmpili Ọlọ́run sílẹ̀ ̀run, a ri àpótí májẹ̀nínú tẹmpili rẹ̀. Mọ̀nàmọ́kọ, a gbọ́ ohùn, àrá sán, ilẹ̀ mi, yìnyín ńlá bọ́.

Seja o primeiro
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-