Publicidade

Jeremias 3

1 "ọkùnrin kan kọ ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀

obìnrin náà lọ fẹ́ ọkọ mìíràn,

ǹjẹ́ ọkùnrin náà tún tọ̀ ́ ?

Ǹjẹ́ ilẹ̀ náà di aláìmọ́ ?

Ṣùgbọ́n ìwọ ti gbé pẹ̀onírúurú panṣágà gẹ́gẹ́ olùfẹ́,

ṣé ìwọ yóò tún padà sọ́dọ̀ mi ?"

ni Olúwa .

2 "Gbé ojú rẹ sókè ibi gíga wọ̀n-ọn-nì,

o ó ibi kan ha a ́ jẹ́?

ojú ̀, ìwọ jókòó de àwọn olólùfẹ́,

i ará Arabia kan nínú aginjù,

ìwọ ti ba ilẹ̀ náà jẹ́

pẹ̀ìwà àgbèrè àti ìwà búburú rẹ.

3 Nítorí náà, a ti fa ̀wààrà òjò sẹ́yìn,

ṣí òjò àrọ̀kúrò.

Síbẹ̀ ìwọ ojú líle ti panṣágà,

ìwọ kọ̀ láti ìtìjú.

4 Ǹjẹ́ ìwọ ha a láìpẹ́ yìí ,

Baba mi, ìwọ ̀rẹ́ mi láti ìgbà èwe mi.

5 Ìwọ yóò ha máa bínú títí?

Ìbínú rẹ yóò ha máa lọ títí láé?

Báyìí ni o ṣe ń sọ̀rọ̀

ìwọ ṣe gbogbo ibi ìwọ le ṣe."

Israẹli aláìṣòótọ́

6 àkókò ìjọba Josiah ọba, Olúwa fún mi , "Ṣé o ti nǹkan àwọn Israẹli aláìnígbàgbọ́ ti ṣe? Wọ́n ti lọ àwọn òkè gíga àti abẹ́ àwọn igi, wọ́n ti ṣe àgbèrè níbẹ̀. 7 Mo nígbà wọ́n ti ṣe èyí wọn yóò padà, wọn padà, Juda aláìgbàgbọ́ arábìnrin rẹ̀ náà i. 8 Mo fún Israẹli aláìnígbàgbọ́ ìwé ìkọ̀sílẹ̀, mo wọn kúrò nítorí gbogbo àgbèrè wọn. Síbẹ̀ mo Juda ó jẹ́ arábìnrin rẹ̀ bẹ̀, òun náà jáde lọ láti lọ ṣe àgbèrè. 9 Nítorí ìwà èérí Israẹli jọ ́ lójú, ó ti ba ilẹ̀ jẹ́, ó ti ṣe àgbèrè pẹ̀òkúta àti igi. 10 Látàrí gbogbo nǹkan wọ̀nyí Juda arábìnrin rẹ̀ aláìgbàgbọ́ padà tọ̀ pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ̀, ṣe nípa fífarahàn olóòtítọ́," ni Olúwa .

11 Olúwa fún mi , "Israẹli aláìnígbàgbọ́ ṣe òdodo ju Juda ó ìgbàgbọ́ lọ. 12 Lọ polongo ̀rọ̀ náà, lọ ìhà àríwá:

" Yípadà, Israẹli aláìnígbàgbọ́,’ ni Olúwa .

Ojú mi yóò korò mọ́,

nítorí mo jẹ́ aláàánú, ni Olúwa .

Èmi yóò bínú mọ́ títí láé.

13 à ti mọ ̀bi rẹ,

ìwọ ti ṣọ̀tẹ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ,

ìwọ ti ojúrere rẹ lọ́dọ̀ ọlọ́run àjèjì

lábẹ́ gbogbo igikígi ó gbilẹ̀,

̀yin gba ohun mi gbọ́,’ "

ni Olúwa .

14 "Padà, ̀yin ènìyàn aláìnígbàgbọ́," ni Olúwa , "nítorí èmi ni ọkọ rẹ. Èmi ó yàn ́, ̀kan láti ìlú àti méjì láti ̀. Èmi ó Sioni. 15 Lẹ́yìn èyí, èmi ó fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn láti inú ọkàn mi, wọn yóò ṣáájú yín pẹ̀òye àti ìmọ̀. 16 ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, ̀yin pọ̀ i lórí ilẹ̀ náà," ni Olúwa , "àwọn ènìyàn tún sọ , Àpótí ̀Olúwa.ìrántí wọn mọ́, a yóò pàdánù rẹ̀, bẹ́̀ ni a yóò tún kan òmíràn mọ́. 17 ìgbà náà, wọn yóò pe Jerusalẹmu ìtẹ́ Olúwa gbogbo orílẹ̀-èdè yóò péjọ Jerusalẹmu láti bọ̀wọ̀ fún orúkọ Olúwa, wọn yóò tún tẹ̀àyà líle búburú wọn mọ́. 18 ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì ni ilé Juda yóò darapọ̀ mọ́ ilé Israẹli. Wọn yóò láti ilẹ̀ àríwá ilẹ̀ mo fi fún àwọn baba ńlá yín gẹ́gẹ́ ilẹ̀ ìní.

19 "Èmi fúnra mi sọ ,

" Báwo ni inú mi yóò ti dùn ,

èmi ó tọ́ ọmọkùnrin

n fún ilẹ̀ ó .

Mo ìwọ yóò Baba mi

o ṣàì tọ̀ lẹ́yìn.

20 Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ aláìgbàgbọ́ obìnrin ọkọ rẹ̀,

bẹ́̀ gẹ́gẹ́ o jẹ́ aláìgbàgbọ́ mi. Ìwọ ilé Israẹli,"

ni Olúwa .

21 A gbọ́ ohùn àgàn láti ibi gíga,

ẹkún àti ̀bẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli,

nítorí wọ́n ti ̀wọn po,

wọ́n ti gbàgbé Olúwa Ọlọ́run wọn.

22 "Padà, ̀yin ènìyàn aláìnígbàgbọ́,

Èmi ó wo ìpadàsẹ́yìn kúrò ̀títọ́ rẹ sàn."

"Bẹ́̀, ni a ó sọ́dọ̀ rẹ

nítorí ìwọ ni Olúwa Ọlọ́run wa.

23 Nítòótọ́, asán ni ìbọ̀rìṣà àti ìrúkèrúdò ó àwọn orí òkè

kéékèèké àti àwọn òkè gíga,

nítòótọ́, nínú Olúwa Ọlọ́run

wa ni ìgbàlà Israẹli .

24 Láti ìgbà èwe wa ni àwọn òrìṣà ìtìjú ti

jẹ èso iṣẹ́ àwọn baba wa run,

̀wọ́ ẹran wọn àti agbo ẹran wọn,

ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin wọn.

25 Jẹ́ a dùbúlẹ̀ nínú ìtìjú wa,

ìtìjú wa mọ́lẹ̀.

A ti ṣẹ̀ Olúwa Ọlọ́run wa,

àwa àti àwọn baba wa,

láti ìgbà èwe wa títí di òní

a gbọ́rọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-