Publicidade

Êxodo 37

Àpótí náà

1 37.1-9: Ek 25.10-22. Besaleli fi igi ṣittimu ṣe àpótí náà, ìgbọ̀nwọ́ méjì ààbọ̀ ni gígùn rẹ̀, ìgbọ̀nwọ́ kan ààbọ̀ ni fífẹ̀ rẹ̀, ìgbọ̀nwọ́ kan ààbọ̀ ni gíga rẹ̀. 2 Ó fi ojúlówó wúrà ó inú àti òde, ó fi wúrà gbá etí rẹ̀ yíká. 3 Ó da òrùka wúrà mẹ́rin fún, láti fi wọ́n igun mẹ́rẹ̀̀rin ẹsẹ̀ rẹ̀, òrùka wúrà méjì yóò ̀gbẹ́ kìn-ín-ní, òrùka wúrà méjì yóò ẹgbẹ́ kejì. 4 Ó fi igi kasia ṣe ̀, ó fi wúrà wọ́n. 5 Ó fi ̀náà bọ òrùka ̀gbẹ́ kọ̀̀kan àpótí ̀náà láti fi gbé e.

6 Ó fi ojúlówó wúrà ṣe ìtẹ́ àánú; ìgbọ̀nwọ́ méjì àti ààbọ̀ gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ kan ààbọ̀ fífẹ̀. 7 Ó ṣe kérúbù méjì láti inú wúrà a fi òòlù igun ìtẹ́ àánú náà. 8 Ó ṣe kérúbù kan igun kìn-ín-ní, àti kérúbù kejì igun kejì; kérúbù náà jẹ́ irú kan náà igun méjèèjì pẹ̀ìbòrí wọn. 9 Àwọn kérúbù na ìyẹ́ apá wọn sókè, wọn yóò fi ìyẹ́ apá wọn ṣe ibòòji orí ìtẹ́ àánú. Àwọn kérúbù náà yóò kọ ojú ara wọn, wọn yóò máa wo ̀kánkán ìtẹ́.

Tábìlì náà

10 37.10-16: Ek 25.23-29. Ó ṣe tábìlì igi ṣittimu ìgbọ̀nwọ́ méjì gígùn, ìgbọ̀nwọ́ kan fífẹ̀, àti ìgbọ̀nwọ́ kan ààbọ̀ gíga. 11 Ó fi ojúlówó wúrà ó, ó ṣe ìgbátí wúrà i . 12 Ó ṣe etí kan ìbú àtẹ́lẹwọ́ i yíká, ó ṣe ìgbátí wúrà etí rẹ̀ . 13 Ó da òrùka wúrà mẹ́rin fún tábìlì náà, ìwọ ó fi òrùka kọ̀̀kan igun mẹ́rẹ̀̀rin ó ẹsẹ̀ rẹ̀ mẹ́rẹ̀̀rin. 14 abẹ́ ìgbátí náà ni àwọn òrùka náà yóò , ààyè láti máa fi gbé tábìlì náà. 15 Ó fi igi kasia ṣe àwọn ̀, ó fi wúrà wọ́n, láti máa fi wọ́n gbé tábìlì náà. 16 Ó ṣe àwọn ohun èlò ó lórí tábìlì náà ojúlówó wúrà, abọ́ rẹ̀, àwo rẹ, àwokòtò rẹ̀ àti ìgò rẹ̀ fún dída ọrẹ mímu jáde.

̀fìtílà náà

17 37.17-24: Ek 25.31-39. Ó ṣe ̀fìtílà náà ojúlówó wúrà, ó ú jáde, ̀rẹ̀, ìtànná ìfẹ́ rẹ̀, ìrudí rẹ àti agogo rẹ̀, wọ́n jẹ́ ̀kan náà. 18 ̀ka mẹ́ni yóò yọ ̀gbẹ́ ̀fìtílà: mẹ́ta ̀gbẹ́ kìn-ín-ní mẹ́ta ni ̀gbẹ́ kejì. 19 Àwo mẹ́ta ni a ṣe ìtànná almondi pẹ̀ìrudí àti ìtànná ni ̀ka kan, mẹ́ta tún ̀ka mìíràn, bẹ́̀ ni ̀ka mẹ́fẹ̀̀jáde lára ̀fìtílà. 20 ara ̀fìtílà ni àwo mẹ́rin ti a ṣe gẹ́gẹ́ òdòdó almondi ti ó ni ìṣọ àti ìtànná yóò . 21 Irúdì kan yóò abẹ́ ̀ka rẹ̀ méjì àkọ́kọ́ ó yọ lára ̀fìtílà, irúdì kejì ó abẹ́ ̀ka rẹ̀ méjì kejì, irúdì kẹta yóò abẹ́ ̀ka rẹ̀ méjì kẹta: ̀ka mẹ́àpapọ̀. 22 Irúdì wọn àti ̀ka wọn ó bákan náà, gbogbo rẹ̀ ó jẹ́ lílù ojúlówó wúrà.

23 Ó ṣe fìtílà rẹ̀, méje, àti alumagaji rẹ̀, àti àwo rẹ̀, kìkì wúrà ni. 24 Ó ṣe ̀fìtílà náà àti gbogbo ohun èlò rẹ̀ láti ara tálẹ́ǹtì kan ó jẹ́ kìkì wúrà.

Pẹpẹ tùràrí

25 37.25-29: Ek 30.1-5. Igi kasia ó fi ṣe pẹpẹ tùràrí náà. Igun mẹ́rẹ̀̀rin rẹ̀ jẹ́ déédé, gígùn rẹ̀ jẹ ìgbọ̀nwọ́ kan, fífẹ̀ rẹ̀ náà jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan àti gíga rẹ̀ jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ méjì, ìwo rẹ̀ jẹ́ bákan náà. 26 Kìkì wúrà ni ó fi bo orí rẹ̀, gbogbo ìhà rẹ̀ àti ìwo rẹ̀, ó fi ìgbátí wúrà yìí . 27 Ó ṣe òrùka wúrà méjì ìsàlẹ̀ ìgbátí náà méjì òdìkejì ara wọn láti gbá òpó náà láti máa fi gbé e. 28 Ó ṣe òpó igi ṣittimu, ó wọ́n pẹ̀u wúrà.

29 Ó túnṣe òróró mímọ́ ìtasórí àti kìkì òórùn dídùn tùràríiṣẹ́ àwọn ń ṣe nǹkan olóòórùn.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-