Publicidade

Números 10

Fèrè ìpè fàdákà

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 "Ṣe fèrè fàdákà méjì pẹ̀fàdákà lílù, o máa ó láti máa fi pe ìjọ ènìyàn àti láti máa fi darí ìrìnàjò lọ ibùdó yín. 3 Nígbà o fọn méjèèjì gbogbo ìjọ ènìyàn yóò síwájú rẹ ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé. 4 ó jẹ́ ̀kan ni o fọn, nígbà náà ni àwọn olórí ̀Israẹli yóò péjọ síwájú rẹ. 5 Nígbà o fun ìpè ìdágìrì, àwọn ̀pa ibùdó ìhà ìlà-oòrùn ni yóò gbéra. 6 Nígbà o fun ìpè ìdágìrì kejì, ibùdó ìhà gúúsù ni yóò gbéra. Ìpè ìdágìrì yìí ni yóò jẹ́ àmì fún gbígbéra. 7 Nígbà o fẹ́ pe ìjọ ènìyàn jọ, fun fèrè nìkan, ṣe fun ti ìdágìrì pẹ̀rẹ̀.

8 "Àwọn ọmọ Aaroni í ṣe àlùfáà ni ó máa fun fèrè. Èyí yóò jẹ́ ìlànà láéláé fún yín àti fún ìran ń bọ̀. 9 Nígbà lọ jagun pẹ̀àwọn ̀ń ni yín lára ilẹ̀ yín, fun ìpè ìdágìrì pẹ̀fèrè. A ó rántí yín níwájú Olúwa, Ọlọ́run yín yóò gbà yín lọ́wọ́ àwọn ̀yín. 10 Bẹ́̀ náà ni ọjọ́ ayọ̀ yín, gbogbo àjọ̀dún a yàn àti ìbẹ̀rẹ̀ oṣù yín, ni máa fun fèrè lórí ẹbọ sísun àti ọrẹ àlàáfíà yín, wọn yóò jẹ́ ìrántí fún yín níwájú Ọlọ́run. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín."

Àwọn ọmọ Israẹli kúrò Sinai

11 ogúnjọ́ oṣù kejì, ọdún kejì ni ìkùùkuu kúrò lórí tabanaku ̀. 12 Àwọn ọmọ Israẹli gbéra kúrò aginjù Sinai wọ́n rin ìrìnàjò wọn káàkiri títí ìkùùkuu fi dúró aginjù Parani. 13 Wọ́n gbéra nígbà àkọ́kọ́ yìí nípa àṣẹ Olúwa láti ẹnu Mose.

14 Àwọn ìpín ti ibùdó Juda kọ́kọ́ gbéra tẹ̀wọn lábẹ́ ogun wọn Nahiṣoni ọmọ Amminadabu ni ̀gágun wọn. 15 Netaneli ọmọ Suari ni ̀gágun ti ̀Isakari; 16 Eliabu ọmọ Heloni ni ̀gágun ni ìpín ti ̀Sebuluni. 17 Nígbà náà ni wọ́n sọ tabanaku kalẹ̀ àwọn ọmọ Gerṣoni àti Merari gbé àgọ́ gbéra.

18 Àwọn ìpín ti ibùdó ti Reubeni gbéra tẹ̀wọn, lábẹ́ ̀págun wọn. Elisuri ọmọ Ṣedeuri ni ̀gágun wọn. 19 Ṣelumieli ọmọ Suriṣaddai ni ̀gágun ti ̀Simeoni. 20 Eliasafu ọmọ Deueli ni ̀gágun ìpín ti ̀Gadi. 21 Nígbà náà ni àwọn ọmọ Kohati ń ru ohun mímọ́ náà gbéra. Àwọn ti àkọ́kọ́ yóò ti gbé tabanaku dúró wọn .

22 Àwọn ìpín ibùdó Efraimu tún kàn lábẹ́ ̀págun wọn. Eliṣama ọmọ Ammihudu ni ̀gágun wọn. 23 Gamalieli ọmọ Pedasuri ni ̀gágun ìpín ti ̀Manase. 24 Abidani ọmọ Gideoni ni ̀gágun ìpín ti ̀Benjamini.

25 Lákòótan, àwọn ọmọ-ogun ń mójútó ̀yìn tún kàn, àwọn ni ìpín ti ibùdó Dani lábẹ́ ̀págun wọn. Ahieseri ọmọ Ammiṣaddai ni ̀gágun wọn. 26 Pagieli ọmọ Okanri ni ìpín ti ̀Aṣeri, 27 Ahira ọmọ Enani ni ̀gágun ti ̀Naftali. 28 Báyìí ni àwọn ọmọ Israẹli ṣe jáde gẹ́gẹ́ ogun nígbà wọ́n bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò wọn.

29 Mose sọ fún Hobabu ọmọ Reueli ará Midiani í ṣe àna rẹ̀ , "A ń gbéra láti lọ ibi Olúwa sọ , Èmi ó fi fún un yín.wa lọ, àwa ó ṣe ́ dáradára nítorí Olúwa ti ṣèlérí ohun rere fún Israẹli."

30 Ó dáhùn , "Rárá, èmi yín lọ, ń padà lọ ilẹ̀ mi àti ̀dọ̀ àwọn ènìyàn mi."

31 Mose sọ , "Jọ̀wọ́ ma fi sílẹ̀, ìwọ mọ ibi a pa ibùdó nínú aginjù, ìwọ yóò jẹ́ ojú fún wa. 32 o wa lọ, a ó pín fún nínú ohun rere yówù Olúwa fún wa."

33 Wọ́n gbéra láti orí òkè Olúwa ìrìn ọjọ́ mẹ́ta. Àpótí ̀Olúwa ń lọ níwájú wọn fún gbogbo ọjọ́ mẹ́ta yìí láti ibi ìsinmi fún wọn. 34 Ìkùùkuu Olúwa lórí wọn lọ́sàn nígbà wọ́n gbéra kúrò ibùdó.

35 10.35: Sm 68.1,2. Nígbàkígbà àpótí ̀gbéra Mose yóò ,

"Dìde, Olúwa!

a àwọn ̀rẹ ,

àwọn ó kórìíra rẹ sálọ níwájú rẹ."

36 Nígbàkígbà àpótí ̀sinmi yóò ,

"Padà, Olúwa,

sọ́dọ̀ àwọn àìmoye ẹgbẹẹgbẹ̀rún Israẹli."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-