Publicidade

Números 7

Ọrẹ níbi ìyàsímímọ́ àgọ́

1 Nígbà Mose ti parí gbígbé àgọ́ dúró, ó ta òróró i, ó á mímọ́ pẹ̀gbogbo àwọn ohun èlò rẹ̀, Ó tún ta òróró pẹpẹ, ó á mímọ́ pẹ̀gbogbo ohun èlò rẹ̀. 2 Nígbà náà ni àwọn olórí Israẹli, àwọn ̀kọ̀̀kan, àwọn alábojútó àwọn a náà ọrẹ . 3 Wọ́n ọrẹ wọn síwájú Olúwa: kẹ̀kẹ́ ẹrù mẹ́ti abo, àti akọ màlúù kan láti ̀dọ̀ olórí kọ̀̀kan àti kẹ̀kẹ́ ẹrù kan láti ̀dọ̀ olórí méjì. Wọ́n wọn iwájú àgọ́.

4 Olúwa sọ fún Mose , 5 "Gba gbogbo nǹkan wọ̀nyí lọ́wọ́ wọn, wọ́n ba à wúlò fún iṣẹ́ inú àgọ́ ìpàdé. wọn fún àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ iṣẹ́ ẹnìkọ̀̀kan ṣe nílò rẹ̀."

6 Mose àwọn kẹ̀kẹ́ ẹrù àti akọ màlúù náà fún àwọn ọmọ Lefi. 7 Ó fún àwọn ọmọ Gerṣoni kẹ̀kẹ́ méjì àti akọ màlúù mẹ́rin, gẹ́gẹ́ iṣẹ́ wọn ṣe jẹ mọ́. 8 Ó fún àwọn ọmọ Merari kẹ̀kẹ́ mẹ́rin àti akọ màlúù mẹ́jọ gẹ́gẹ́ iṣẹ́ wọn ṣe jẹ mọ́. Gbogbo wọn lábẹ́ àkóso Itamari ọmọ Aaroni í ṣe àlùfáà. 9 Ṣùgbọ́n Mose fún àwọn ọmọ Kohati nǹkan kan nítorí èjìká wọn ni wọn yóò fi ru àwọn ohun mímọ́ èyí ó jẹ́ ojúṣe tiwọn.

10 Nígbà a ta òróró sórí pẹpẹ. Àwọn olórí àwọn ọrẹ wọn fún ìyàsímímọ́ rẹ̀, wọ́n wọn síwájú pẹpẹ. 11 Nítorí Olúwa ti sọ fún Mose , "Olórí kọ̀̀kan ọjọ́ kọ̀̀kan ni yóò máa ọrẹ tirẹ̀ fún ìyàsímímọ́ pẹpẹ."

12 Ẹni ó ọrẹ tirẹ̀ ọjọ́ kìn-ín-ní Nahiṣoni ọmọ Amminadabu láti inú ̀Juda.

13 Ọrẹ rẹ̀ jẹ́:

àwo fàdákà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò ti fàdákà ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́ àwo kọ̀̀kan kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára a fi òróró gẹ́gẹ́ ẹbọ ohun jíjẹ;

14 àwo wúrà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá ó kún fún tùràrí;

15 ̀dọ́ akọ màlúù kan, àgbò kan, akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun,

16 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀,

17 akọ màlúù méjì, àgbò márùn-ún, òbúkọ ọlọ́dún kan márùn-ún wọn ó fi ẹbọ àlàáfíà.

Wọ̀nyí ni ọrẹ Nahiṣoni ọmọ Amminadabu.

18 ọjọ́ kejì ni Netaneli ọmọ Suari olórí àwọn ọmọ Isakari ọrẹ tirẹ̀ .

19 Ọrẹ ó :

àwo fàdákà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀̀kan kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára á fi òróró gẹ́gẹ́ ẹbọ ohun jíjẹ;

20 àwo wúrà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá ó kún fún tùràrí,

21 ̀dọ́ akọ màlúù kan, àgbò kan, àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan, fún ẹbọ sísun;

22 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀;

23 Màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún wọn ó fi ẹbọ àlàáfíà.

Èyí ni ọrẹ Netaneli ọmọ Suari.

24 Eliabu ọmọ Heloni, olórí àwọn ọmọ Sebuluni ni ó ọrẹ rẹ̀ ọjọ́ kẹta.

25 Àwọn ọrẹ rẹ̀ ni:

àwo fàdákà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀̀kan kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára á fi òróró gẹ́gẹ́ ẹbọ ohun jíjẹ;

26 àwo wúrà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá ó kún fún tùràrí;

27 akọ ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;

28 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀;

29 Màlúù méjì, àgbò márùn-ún, òbúkọ márùn-ún akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún wọn o fi ẹbọ àlàáfíà.

Èyí ni ọrẹ Eliabu ọmọ Heloni.

30 Elisuri ọmọ Ṣedeuri olórí àwọn ọmọ Reubeni ni ó ọrẹ ọjọ́ kẹrin.

31 Ọrẹ rẹ̀ ni:

àwo fàdákà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀̀kan kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára á fi òróró gẹ́gẹ́ ẹbọ ohun jíjẹ;

32 àwo wúrà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá ó kún fún tùràrí,

33 akọ ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;

34 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀;

35 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún wọn ó fi ẹbọ àlàáfíà.

Èyí ni ọrẹ Elisuri ọmọ Ṣedeuri.

36 Ṣelumieli ọmọ Suriṣaddai, olórí àwọn ọmọ Simeoni ni ó ọrẹ ọjọ́ karùn-ún.

37 Ọrẹ ó ni:

àwo fàdákà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀̀kan kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára á fi òróró gẹ́gẹ́ ẹbọ ohun jíjẹ;

38 àwo wúrà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá ó kún fún tùràrí;

39 akọ ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;

40 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀;

41 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún wọn ó fi ẹbọ àlàáfíà.

Èyí ni ọrẹ Ṣelumieli ọmọ Suriṣaddai.

42 Eliasafu ọmọ Deueli olórí àwọn ọmọ Gadi ó ọrẹ rẹ̀ ọjọ́ kẹfà.

43 Ọrẹ rẹ̀ ni:

àwo fàdákà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀̀kan kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára á fi òróró gẹ́gẹ́ ẹbọ ohun jíjẹ;

44 àwo wúrà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá ó kún fún tùràrí;

45 akọ ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;

46 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀;

47 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún, wọn ó fi ẹbọ àlàáfíà.

Èyí ni ọrẹ Eliasafu ọmọ Deueli.

48 Eliṣama ọmọ Ammihudu, olórí àwọn ọmọ Efraimu ni ó ọrẹ rẹ̀ ọjọ́ keje.

49 Ọrẹ rẹ̀ ni:

àwo fàdákà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀̀kan kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára á fi òróró gẹ́gẹ́ ẹbọ ohun jíjẹ;

50 àwo wúrà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá ó kún fún tùràrí;

51 akọ ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;

52 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀;

53 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún, wọn ó fi ẹbọ àlàáfíà.

Èyí ni ọrẹ Eliṣama ọmọ Ammihudu.

54 Gamalieli ọmọ Pedasuri, olórí àwọn ọmọ Manase ni ó ọrẹ tirẹ̀ ọjọ́ kẹjọ.

55 Ọrẹ tirẹ̀ ni:

àwo fàdákà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀̀kan kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára á fi òróró gẹ́gẹ́ ẹbọ ohun jíjẹ;

56 àwo wúrà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá ó kún fún tùràrí;

57 akọ ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;

58 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀;

59 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún wọn ó fi ẹbọ àlàáfíà.

Èyí ni ọrẹ Gamalieli ọmọ Pedasuri.

60 Abidani ọmọ Gideoni, olórí àwọn ọmọ Benjamini ni ó ọrẹ tirẹ̀ ọjọ́ kẹsànán.

61 Ọrẹ rẹ̀ ni:

àwo fàdákà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀̀kan kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára á fi òróró gẹ́gẹ́ ẹbọ ohun jíjẹ;

62 àwo wúrà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá ó kún fún tùràrí;

63 akọ ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;

64 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀;

65 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún wọn ó fi ẹbọ àlàáfíà.

Èyí ni ọrẹ Abidani ọmọ Gideoni.

66 Ahieseri ọmọ Ammiṣaddai, olórí àwọn ọmọ Dani ni ó ọrẹ tirẹ̀ ọjọ́ kẹwàá.

67 Ọrẹ rẹ̀ ni:

àwo fàdákà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀̀kan kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára á fi òróró gẹ́gẹ́ ẹbọ ohun jíjẹ;

68 àwo wúrà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá ó kún fún tùràrí;

69 akọ ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;

70 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀;

71 àti fún ẹbọ ti ẹbọ àlàáfíà, akọ màlúù méjì, àgbò márùn-ún, òbúkọ márùn-ún, akọ ̀dọ́-àgùntàn márùn-ún ọlọ́dún kan.

Èyí ni ọrẹ ẹbọ Ahieseri ọmọ Ammiṣaddai.

72 Pagieli ọmọ Okanri, olórí àwọn ọmọ Aṣeri ni ó ọrẹ rẹ̀ ọjọ́ kọkànlá.

73 Ọrẹ rẹ̀ ni:

àwo fàdákà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀̀kan kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára á fi òróró gẹ́gẹ́ ẹbọ ohun jíjẹ;

74 àwo wúrà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá ó kún fún tùràrí;

75 akọ ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;

76 akọ ewúrẹ́ fún ẹbọ ̀ṣẹ̀;

77 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún, wọn ó fi ẹbọ àlàáfíà.

Èyí ni ọrẹ Pagieli ọmọ Okanri.

78 Ahira ọmọ Enani, olórí àwọn Naftali ni ó ọrẹ rẹ̀ ọjọ́ kejìlá.

79 Ọrẹ rẹ̀ ni:

àwo fàdákà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀̀kan kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára á fi òróró gẹ́gẹ́ ẹbọ ohun jíjẹ;

80 àwo wúrà kan ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá ó kún fún tùràrí;

81 akọ ̀dọ́ màlúù kan àgbò kan, àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;

82 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀;

83 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún, wọn ó fi ẹbọ àlàáfíà.

Èyí ni ọrẹ Ahira ọmọ Enani.

84 Wọ̀nyí ni ọrẹ àwọn olórí àwọn ọmọ Israẹli fún ìyàsímímọ́ pẹpẹ nígbà wọ́n ta òróró i lórí:

àwo fàdákà méjìlá, àwokòtò méjìlá, àwo wúrà méjìlá. 85 Àwo fàdákà kọ̀̀kan wọn àádóje ṣékélì, àwokòtò kọ̀̀kan wọn àádọ́rin. Àpapọ̀ gbogbo àwo fàdákà jẹ́ egbèjìlá (2,400) ṣékélì gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́. 86 ̀kọ̀̀kan àwo wúrà méjìlá tùràrí kún inú wọn ṣékélì mẹ́wàá mẹ́wàá gẹ́gẹ́ iye owó ibi mímọ́. Àpapọ̀ ìwọ̀n gbogbo àwo wúrà jẹ́ ọgọ́ṣékélì.

87 Àpapọ̀ iye ẹran fún ẹbọ sísun jẹ́ akọ ̀dọ́ màlúù méjìlá, àgbò méjìlá, akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan méjìlá pẹ̀ọrẹ ohun jíjẹ. Akọ ewúrẹ́ fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ jẹ́ méjìlá.

88 Àpapọ̀ iye ẹran fún ọrẹ àlàáfíà jẹ́ màlúù mẹ́rìnlélógún, ọgọ́ta àgbò, ọgọ́ta akọ ewúrẹ́ àti ọgọ́ta akọ ̀dọ́ màlúù ọlọ́dún kan.

Wọ̀nyí ni ọrẹ ìyàsímímọ́ pẹpẹ lẹ́yìn a ta òróró i.

89 Nígbà Mose wọ inú àgọ́ ìpàdé láti Olúwa sọ̀rọ̀, Olúwa sọ̀rọ̀ i láti àárín àwọn kérúbù méjì láti orí ìtẹ́ àánú ó bo àpótí ̀, ohùn náà Mose sọ̀rọ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-