Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Reis 18

Elijah àti Obadiah

1 Ó ṣe, lẹ́yìn ọjọ́ púpọ̀, ọdún kẹta, ̀rọ̀ Olúwa tọ Elijah , "Lọ, o fi ara rẹ̀ hàn fún Ahabu, èmi yóò rọ òjò sórí ilẹ̀." 2 Bẹ́̀ ni Elijah lọ fi ara rẹ̀ han Ahabu.

Ìyàn ńlá Samaria, 3 Ahabu ti pe Obadiah, ẹni ń ṣe olórí ilé rẹ̀. Obadiah bẹ̀Olúwa gidigidi. 4 Nígbà Jesebeli ń pa àwọn wòlíì Olúwa kúrò, Obadiah ọgọ́rùn-ún wòlíì, ó fi wọ́n pamọ́ sínú ihò òkúta, àádọ́ta ihò kọ̀̀kan, ó fi àkàrà pẹ̀omi bọ́ wọn. 5 Ahabu ti fún Obadiah , "Lọ gbogbo ilẹ̀ orísun omi gbogbo àti ilẹ̀ gbogbo. Bóyá àwa koríko láti gba àwọn ẹṣin àti àwọn ìbáaka , a à ṣòfò àwọn ẹranko pátápátá." 6 Bẹ́̀ ni wọ́n pín ilẹ̀ wọ́n fẹ́ láàrín ara wọn, Ahabu gba ̀kan lọ, Obadiah gba ̀mìíràn lọ.

7 Obadiah ti ń rìn lọ, Elijah pàdé rẹ̀. Obadiah mọ̀ ́n, ó dojúbolẹ̀, ó , "Ǹjẹ́ ìwọ ni nítòótọ́, Elijah, olúwa mi?"

8 Elijah a lóhùn , "Bẹ́̀ ni, lọ o sọ fún olúwa rẹ , Elijah ń bẹ níhìn-ín.’ "

9 Obadiah béèrè , "̀ṣẹ̀ ni mo ha ìwọ fi ń fi ìránṣẹ́ rẹ Ahabu lọ́wọ́ láti pa? 10 Mo mọ̀ dájú Olúwa Ọlọ́run rẹ ti ń bẹ, orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan olúwa mi ti rán ènìyàn lọ láti ́. Àti nígbà orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan o , òun a wọ́n búra wọn . 11 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ìwọ fún mi n lọ sọ́dọ̀ olúwa mi, n , Elijah ń bẹ níhìn-ín.12 Èmi mọ ibi ̀Olúwa yóò gbé lọ nígbà mo fi ́ sílẹ̀. mo lọ, mo sọ fún Ahabu, , òun a pa . Síbẹ̀ èmi ìránṣẹ́ rẹ bẹ̀Olúwa láti ìgbà èwe mi . 13 Ṣé Olúwa mi ha ti gbọ́ ohun mo ṣe nígbà Jesebeli ń pa àwọn wòlíì Olúwa? Mo fi ọgọ́rùn-ún wòlíì Olúwa pamọ́ sínú ihò òkúta méjì, àràádọ́ta ̀kọ̀̀kan, mo fi omi àti oúnjẹ bọ́ wọn. 14 Ìwọ sọ fún mi nísinsin yìí , n tọ olúwa mi lọ , Elijah ń bẹ níhìn-ín.Òun a pa !"

15 Elijah , "Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti , ẹni èmi ń sìn, nítòótọ́ èmi yóò fi ara mi hàn fún Ahabu lónìí."

Elijah lórí òkè Karmeli

16 Bẹ́̀ ni Obadiah lọ láti pàdé Ahabu, ó sọ fún un, Ahabu lọ láti pàdé Elijah. 17 Nígbà Ahabu Elijah, ó fún un , "Ṣé ìwọ nìyìí, ìwọ ń yọ Israẹli lẹ́nu?"

18 Elijah a lóhùn , "Èmi yọ Israẹli lẹ́nu, ṣe ìwọ àti ilé baba rẹ. ti kọ òfin Olúwa sílẹ̀, ń tọ Baali lẹ́yìn. 19 Nísinsin yìí gbogbo Israẹli jọ láti pàdé mi lórí òkè Karmeli. Àti o àádọ́ta irinwó (450) àwọn wòlíì Baali àti irinwó (400) àwọn wòlíì òrìṣà Aṣerah wọ́n ń jẹun tábìlì Jesebeli."

20 Bẹ́̀ ni Ahabu ránṣẹ́ gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, ó àwọn wòlíì jọ orí òkè Karmeli. 21 Elijah lọ síwájú gbogbo àwọn ènìyàn, ó , "Yóò ti pẹ́ ̀yin yóò máa ṣiyèméjì? Olúwa ni Ọlọ́run, máa tọ̀ ́ lẹ́yìn, ṣùgbọ́n Baali ni Ọlọ́run, máa tọ̀ ́ lẹ́yìn."

Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn náà ohun kan.

22 Nígbà náà ni Elijah fún wọn , "Èmi nìkan ṣoṣo ni ó wòlíì Olúwa, ṣùgbọ́n, àádọ́ta irinwó (450) ni wòlíì Baali. 23 fún wa ẹgbọrọ akọ màlúù méjì. Jẹ́ wọn ó yan ẹgbọrọ akọ màlúù kan fún ara wọn, wọn ó e wẹ́wẹ́, wọn ó ó orí igi, wọn ó ṣe fi iná i. Èmi yóò tún ẹgbọrọ akọ màlúù kejì ṣe, èmi yóò ó sórí igi, èmi yóò fi iná i. 24 Nígbà náà ó pe orúkọ àwọn Ọlọ́run yín, èmi yóò pe orúkọ Olúwa. Ọlọ́run náà ó fi iná dáhùn, òun ni Ọlọ́run."

Nígbà náà ni gbogbo àwọn ènìyàn náà , "Ohun ìwọ sọ dára."

25 Elijah fún àwọn wòlíì Baali , "yan ẹgbọrọ akọ màlúù kan fún ara yín, tètè kọ́ ṣe é, nítorí ̀yin pọ̀. pe orúkọ àwọn ọlọ́run yín, ṣùgbọ́n ṣe fi iná i." 26 Nígbà náà ni wọ́n ẹgbọrọ akọ màlúù náà, a ti fi fún wọn, wọ́n ṣe é.

Nígbà náà ni wọ́n pe orúkọ Baali láti òwúrọ̀ títí di ̀sán gangan , "Baali! wa lóhùn!" Wọ́n ń kégbe. Ṣùgbọ́n ìdáhùn; ẹnìkan ó dáhùn. Wọ́n pẹpẹ náà , èyí wọ́n tẹ́.

27 ̀sán gangan, Elijah bẹ̀rẹ̀ ń fi wọ́n ṣe ẹlẹ́ó , "kígbe lóhùn rara Ọlọ́run à ni òun! Bóyá ó ń ṣe àṣàrò, tàbí ráyè, tàbí ó re àjò. Bóyá ó sùn, ó yẹ a i." 28 Bẹ́̀ ni wọ́n kígbe lóhùn rara, wọ́n fi ̀bẹ àti ̀kọ̀ ya ara wọn gẹ́gẹ́ ìṣe wọn, títí ̀jẹ̀ fi jáde ara wọn. 29 Nígbà ọjọ́ yẹ àtàrí, wọ́n ń fi òmùgọ̀ sọtẹ́lẹ̀ títí di àkókò ìrúbọ àṣálẹ́, ṣùgbọ́n ohùn, ṣí ìdáhùn, ṣí ẹni ó á .

30 Nígbà náà ni Elijah fún gbogbo àwọn ènìyàn náà , "súnmọ́ mi." Wọ́n súnmọ́ ọn, ó tún pẹpẹ Olúwa ó ti lulẹ̀ ṣe. 31 Elijah òkúta méjìlá, ̀kọ̀̀kan fún ̀ọmọ Jakọbu kan, ẹni ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ , "Israẹli ni orúkọ rẹ̀ yóò máa jẹ́." 32 Ó tẹ́ pẹpẹ pẹ̀àwọn òkúta wọ̀nyí orúkọ Olúwa, ó wa yàrá pẹpẹ náà , ó gba ìwọ̀n òsùwọ̀n irúgbìn méjì. 33 Ó to igi náà dáradára, ó ẹgbọrọ akọ màlúù náà wẹ́wẹ́, ó ó sórí igi. Nígbà náà ni ó fún wọn , "fi omi kún ìkòkò mẹ́rin, tu sórí ẹbọ sísun àti sórí igi náà."

34 Ó pe, "ṣe é ìgbà kejì." Wọ́n ṣe é ìgbà kejì.

Ó tún , "Ṣe é ìgbà kẹta." 35 Omi náà sàn pẹpẹ náà , ó fi omi kún yàrá náà pẹ̀.

36 Ó ṣe, ìrúbọ àṣálẹ́, wòlíì Elijah súnmọ́ tòsí, ó gbàdúrà , "Olúwa, Ọlọ́run Abrahamu, Isaaki àti Israẹli, jẹ́ ó di mọ̀ lónìí ìwọ ni Ọlọ́run Israẹli àti èmi ni ìránṣẹ́ rẹ, àti mo ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí nípa àṣẹ rẹ. 37 Gbọ́ ti èmi, Olúwa, gbọ́ ti èmi, àwọn ènìyàn wọ̀nyí mọ̀ ìwọ Olúwa ni Ọlọ́run àti ìwọ tún ọkàn wọn padà."

38 Nígbà náà ni iná Olúwa bọ́ sílẹ̀, ó sun ẹbọ sísun náà àti igi, àti àwọn òkúta, àti erùpẹ̀, ó tún omi ń bẹ nínú yàrá náà.

39 Nígbà gbogbo àwọn ènìyàn èyí, wọ́n da ojú wọn bolẹ̀, wọ́n kígbe , "Olúwa, òun ni Ọlọ́run! Olúwa, òun ni Ọlọ́run!"

40 Nígbà náà ni Elijah pàṣẹ fún wọn , "àwọn wòlíì Baali. ṣe jẹ́ ̀kan nínú wọn ó sálọ!" Wọ́n wọn, Elijah wọn sọ̀kalẹ̀ àfonífojì Kiṣoni, ó pa wọ́n níbẹ̀.

41 Elijah fún Ahabu , "Lọ, jẹ, o mu, nítorí ìró ̀pọ̀lọpọ̀ òjò ń bọ̀." 42 Bẹ́̀ ni Ahabu gòkè lọ láti jẹ àti láti mu. Ṣùgbọ́n Elijah gun orí òkè Karmeli lọ ó tẹríba, ó fi ojú rẹ̀ agbede-méjì eékún rẹ̀.

43 Ó fún ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ , "Lọ, o wo ìhà Òkun, òun gòkè lọ, ó ."

Ó , "nǹkan níbẹ̀."

Ó , "Tún lọ nígbà méje."

44 Nígbà keje, ìránṣẹ́ náà , "Àwọsánmọ̀ kékeré kan dìde láti inú Òkun, gẹ́gẹ́ ọwọ́ ènìyàn."

Elijah , "Lọ, o sọ fún Ahabu , Di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ, o sọ̀kalẹ̀ lọ, òjò ó ba à dúró.’ "

45 Ó ṣe, nígbà díẹ̀ i, ̀run ṣú fún àwọsánmọ̀, ìjì dìde, òjò púpọ̀ rọ̀, Ahabu gun kẹ̀kẹ́ lọ Jesreeli. 46 Agbára Olúwa ń bẹ lára Elijah; ó di àmùrè ̀gbẹ́ rẹ, ó sáré níwájú Ahabu títí Jesreeli.

Veja também