Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuẹli 16

Samuẹli fi òróró yan Dafidi

1 Olúwa sọ fún Samuẹli , "Yóò ha ti pẹ́ ìwọ yóò máa dárò Saulu, nígbà ó jẹ́ mo ti kọ̀ ́ ọba lórí Israẹli? Rọ òróró kún inú ìwo rẹ, o ̀rẹ pọ̀n, Èmi rán Jese ará Bẹtilẹhẹmu. Èmi ti yan ̀kan lára àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ láti jẹ ọba."

2 Ṣùgbọ́n Samuẹli , "Báwo ni èmi yóò ṣe lọ? Saulu gbọ́ nípa rẹ̀, yóò pa mi."

Olúwa , "abo ẹgbọrọ màlúù kan pẹ̀rẹ, o , Èmi láti ẹbọ Olúwa.3 Pe Jese ibi ìrúbọ náà, Èmi yóò fi ohun ìwọ yóò ṣe hàn ́. Ìwọ yóò fi òróró yàn fún mi, ẹni èmi fihàn ́."

4 Samuẹli ṣe ohun Olúwa sọ. Nígbà ó Bẹtilẹhẹmu, àyà gbogbo àgbàgbà ìlú , nígbà wọ́n pàdé rẹ̀. Wọ́n béèrè , "Ṣé àlàáfíà ìwọ ?"

5 Samuẹli dáhùn , "Bẹ́̀ ni àlàáfíà ni; mo láti ẹbọ Olúwa. ya ara yín mímọ́, ẹbọ pẹ̀mi." Nígbà náà ni ó ya Jese mímọ́ pẹ̀àwọn ọmọ rẹ̀, ó wọ́n ibi ìrúbọ náà.

6 Nígbà wọ́n , Samuẹli Eliabu, ó nínú ara rẹ̀ lóòótọ́ ẹni òróró Olúwa dúró níbí níwájú Olúwa.

7 Ṣùgbọ́n Olúwa sọ fún Samuẹli , "ṣe wo ti ìrísí rẹ̀ tàbí ti gíga rẹ̀, nítorí èmi ti kọ̀ ́ sílẹ̀. Olúwa í wo ohun ènìyàn máa ń . Ènìyàn máa ń wo òde ara ṣùgbọ́n Olúwa máa ń wo ọkàn."

8 Nígbà náà ni Jese pe Abinadabu, ó jẹ́ ó rìn kọjá iwájú Samuẹli. Ṣùgbọ́n Samuẹli , "Olúwa yan ẹni yìí." 9 Jese jẹ́ Ṣamma rìn kọjá iwájú Samuẹli, ṣùgbọ́n Samuẹli , "Olúwa yan ẹni yìí náà." 10 Jese jẹ́ àwọn ọmọ rẹ̀ méje rìn kọjá iwájú Samuẹli ṣùgbọ́n Samuẹli sọ fún un , "Olúwa yan àwọn wọ̀nyí." 11 Nígbà náà ni ó béèrè lọ́wọ́ Jese , "Ṣé èyí ni gbogbo àwọn ọmọ rẹ?"

Jese dáhùn , "Ó ku àbíkẹ́yìn wọn, ó ń tọ́agbo àgùntàn."

Samuẹli , "Rán ìránṣẹ́ lọ é ; àwa jókòó títí òun yóò fi ."

12 Ó ránṣẹ́ i, wọ́n un wọlé , ó jẹ́ ẹni mọ́ra, àwọ̀ ara rẹ̀ dùn ún , ó jẹ́ arẹwà gidigidi.

Nígbà náà ni Olúwa , "Dìde o fi òróró yàn án, òun ni ẹni náà."

13 Nígbà náà ni Samuẹli ìwo òróró, ó ta á i orí iwájú àwọn ̀gbọ́n rẹ̀, láti ọjọ́ náà lọ, ̀Mímọ́ Olúwa orí Dafidi nínú agbára. Samuẹli lọ Rama.

Dafidi nínú iṣẹ́ Saulu

14 Nísinsin yìí, ̀Olúwa ti kúrò lára Saulu, ̀búburú láti ̀dọ̀ Olúwa ń yọ ́ lẹ́nu.

15 Àwọn ìránṣẹ́ Saulu fún un , "ó, ̀búburú láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ń yọ ́ lẹ́nu. 16 Jẹ́ olúwa wa pàṣẹ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ó níhìn-ín láti wa ẹnìkan ó fi dùùrù kọrin. Yóò ṣe é nígbà ̀búburú láti ̀dọ̀ Ọlọ́run , ìwọ yóò sàn."

17 Nígbà náà ni Saulu fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ , "ẹnìkan ó kọrin dáradára u fún mi."

18 ̀kan nínú ìránṣẹ́ náà dáhùn , "Èmi ti ri ̀kan nínú àwọn ọmọ Jese ti Bẹtilẹhẹmu ó mọ orin kọ, ó jẹ́ alágbára àti ológun. Ó ọgbọ́n ̀rọ̀ òun dára wíwò. Olúwa pẹ̀u rẹ̀."

19 Saulu rán oníṣẹ́ Jese , "Rán Dafidi ọmọ rẹ mi, ẹni ó ń ṣọ́ àgùntàn." 20 Jese kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ti a di ẹrù àti ìgò ọtí wáìnì àti ọmọ ewúrẹ́; ó rán wọn nípa ọwọ́ Dafidi ọmọ rẹ̀ Saulu.

21 Dafidi tọ Saulu lọ, ó dúró níwájú rẹ̀, òun fẹ́ gidigidi, Dafidi di ̀kan nínú àwọn ń ru ìhámọ́ra rẹ̀. 22 Nígbà náà ni Saulu ránṣẹ́ Jese , "Jẹ́ Dafidi dúró níwájú mi, nítorí ó ."

23 Ó ṣe, nígbà ̀búburú láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Saulu, Dafidi a fi ọwọ́ rẹ̀ kọrin lára dùùrù: a san fún Saulu, ara rẹ̀ a ; ̀búburú náà a fi sílẹ̀.

Veja também