Publicidade

2 Reis 20

Àìsàn Hesekiah

1 ayé ìgbà wọ̀n-ọn-nì Hesekiah ṣe àìsàn ó ojú ikú. Wòlíì Isaiah ọmọ Amosi lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ ó , "Èyí ni ohun Olúwa sọ: tún ilé rẹ ṣe, ṣùgbọ́n ìwọ yóò ; o í gbádùn."

2 Hesekiah ojú rẹ̀ padà ògiri ó gbàdúrà Olúwa , 3 "Rántí, Olúwa mi, èmi ṣe rìn níwájú rẹ àti pẹ̀èmi ṣe jẹ́ olóòtítọ́ àti pẹ̀gbogbo ọkàn ìfọkànsìn mi èmi ti ṣe ohun ó dára níwájú rẹ." Hesekiah sọkún kíkorò.

4 ó di Isaiah jáde kúrò àárín àgbàlá ààfin, ̀rọ̀ Olúwa ̀dọ̀ rẹ̀ : 5 "Lọ padà o sọ fún Hesekiah, olórí àwọn ènìyàn mi , Èyí ni ohun Olúwa, Ọlọ́run baba rẹ Dafidi sọ: Mo ti gbọ́ àdúrà rẹ mo ti omijé rẹ, Èmi yóò ́ sàn. ọjọ́ kẹta láti ìsinsin yìí, ìwọ yóò lọ sókè ilé a kọ́ fún Olúwa. 6 Èmi yóò fi ọdún mẹ́̀́dógún kún ọjọ́ ayé rẹ. Èmi yóò gbà ́ àti ìlú ńlá yìí láti ọwọ́ ọba Asiria. Èmi yóò dáàbò bo ìlú yìí nítorí ti èmi tìkára mi àti nítorí ti Dafidi ìránṣẹ́ mi.’ "

7 Nígbà náà ni Isaiah , "odidi ̀pọ̀tọ́." Wọ́n un, wọ́n fi oówo náà, ara rẹ̀ .

8 Hesekiah béèrè lọ́wọ́ Isaiah , "ni yóò jẹ́ àmì Olúwa yóò sàn àti èmi yóò lọ sókè ilé a kọ́ fún Olúwa láti ọjọ́ kẹta títí di òní?"

9 Isaiah dáhùn , "Èyí ni àmì Olúwa fún Olúwa yóò ṣe ohun ó ti ṣe ìlérí: òjìji lọ síwájú ìgbésẹ̀ mẹ́wàá, tàbí ó padà lọ ìgbésẹ̀ mẹ́wàá?"

10 "Ó jẹ́ ohun ìrọ̀rùn fún òjìji láti lọ síwájú ìgbésẹ̀ mẹ́wàá," Hesekiah , "Bẹ́̀ kọ́, jẹ́ ó lọ padà ìgbésẹ̀ mẹ́wàá."

11 Nígbà náà wòlíì Isaiah pe Olúwa, Olúwa ṣe òjìji padà ìgbésẹ̀ mẹ́wàá ó ti sọ̀kalẹ̀ òpópó ̀Ahasi.

Oníṣẹ́ ọba láti Babeli

12 àkókò náà ni Merodaki-Baladani ọmọ Baladani ọba Babeli ránṣẹ́ ìwé àti ̀bùn Hesekiah nítorí ó ti gbọ́ nípa àìsàn Hesekiah. 13 Hesekiah gba ìránṣẹ́ náà ó fihàn wọ́n, gbogbo ohun ó nínú ilé ìṣúrasílífà, àti wúrà, àti tùràrí, àti òróró dáradára àti ìhámọ́ra àti gbogbo èyí a lára ìṣúra rẹ̀. nǹkan nínú ààfin rẹ̀ tàbí nínú gbogbo ìjọba rẹ̀ Hesekiah fihàn wọ́n.

14 Nígbà náà Isaiah wòlíì lọ ̀dọ̀ ọba Hesekiah ó béèrè , "ni àwọn ọkùnrin náà sọ, àti níbo ni wọ́n ti ń bọ̀ ?"

"Láti ìlú jíjìn réré," Hesekiah dáhùn. "Wọ́n láti Babeli."

15 Wòlíì náà béèrè , "ni wọ́n ààfin rẹ?"

"Wọ́n gbogbo nǹkan ààfin mi," Hesekiah . "nǹkan kan lára àwọn ìṣúra èmi fihàn wọ́n."

16 Nígbà náà Isaiah fún Hesekiah , "Gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa, 17 àkókò náà yóò nítòótọ́ nígbà gbogbo ohun ó ààfin àti gbogbo ohun baba rẹ̀ ti pamọ́ sókè títí di ọjọ́ òní, wọn ó gbe lọ Babeli, ohun yóò , ni Olúwa . 18 Àti díẹ̀ nínú àwọn ìran rẹ, ẹran-ara rẹ àti ̀jẹ̀, wọn yóò fún , ni wọn yóò lọ, wọn yóò di ìwẹ̀ààfin ọba Babeli."

19 Hesekiah fún Isaiah . "Rere ni ̀rọ̀ Olúwa ìwọ sọ." Nítorí ó , "ha dára àlàáfíà àti òtítọ́ ọjọ́ ayé mi?"

20 ti àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tókù nípa ìjọba Hesekiah, gbogbo ohun ó ṣe tan àti ó ti ṣe adágún omi àti ̀omi náà nípa èyí ó gbé omi sínú ìlú ńlá, ṣé wọn kọ wọ́n sínú ìwé ìgbésẹ̀ ayé àwọn ọba àwọn Juda? 21 Hesekiah sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀: Manase ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-