Publicidade

2 Samuel 23

̀rọ̀ ìkẹyìn Dafidi

1 Wọ̀nyí ni ̀rọ̀ ìkẹyìn Dafidi.

"Dafidi ọmọ Jese,

àní ọkùnrin a ti gbéga,

ẹni àmì òróró Ọlọ́run Jakọbu,

àti olórin dídùn Israẹli ,

2 "̀Olúwa sọ ̀rọ̀ nípa mi,

̀rọ̀ rẹ̀ ń bẹ ahọ́n mi.

3 Ọlọ́run Israẹli ni,

àpáta Israẹli sọ fún mi ,

Ẹnìkan ti ń ṣe alákòóso ènìyàn lódodo,

ń ṣàkóso ìbẹ̀Ọlọ́run.

4 Yóò dàbí ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀ nígbà oòrùn ,

òwúrọ̀ ìkùùkuu,

nígbà koríko tútù

láti ilẹ̀ lẹ́yìn òjò.

5 "Lóòtítọ́ ilé mi bẹ́̀ níwájú Ọlọ́run,

ṣùgbọ́n ó ti mi májẹ̀àìnípẹ̀kun,

a túnṣe nínú ohun gbogbo,

a pamọ́; nítorí gbogbo èyí ni ìgbàlà, àti gbogbo ìfẹ́ mi,

ilé mi ṣe ó dàgbà.

6 Ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ọmọ Beliali yóò dàbí ̀gún ̀wọ̀n a ṣá ,

nítorí a fi ọwọ́ wọn.

7 Ṣùgbọ́n ọkùnrin yóò tọ́ wọn yóò

fi irin àti ̀̀kọ̀ ṣagbára ara rẹ̀ ;

wọ́n ó jóná lúúlúú níbìkan náà."

Iṣẹ́ àwọn alágbára Dafidi

8 23.8-39: 1Ki 11.10-41. Wọ̀nyí ni orúkọ àwọn akọni ọkùnrin Dafidi :

Joṣebu-Basṣebeti ará Takemoniti ni olórí àwọn balógun, òun ni akọni rẹ̀ ó pa ẹgbẹ̀rin (800) ènìyàn lẹ́̀kan náà.

9 Ẹni ó tẹ̀e ni Eleasari ọmọ Dodo ará Ahohi, ̀kan nínú àwọn alágbára ọkùnrin mẹ́ta ti ó pẹ̀Dafidi, nígbà wọ́n pe àwọn Filistini ìjà, àwọn ọkùnrin Israẹli ti lọ kúrò. 10 Òun dìde, ó kọlu àwọn Filistini títí ọwọ́ fi kún un, ọwọ́ rẹ̀ lẹ̀ mọ́ idà; Olúwa ṣiṣẹ́ ìgbàlà ńlá lọ́jọ́ náà, àwọn ènìyàn padà bọ̀ lẹ́yìn rẹ̀ láti ìkógun.

11 Ẹni ó tẹ̀e ni Ṣamma ọmọ Agee ará Harari, àwọn Filistini ara wọn jọ láti piyẹ́, oko kan níbẹ̀ ó kún fun lẹntili, àwọn ọmọ-ogun Israẹli kúrò níwájú àwọn Filistini. 12 Ṣamma dúró láàrín méjì ilẹ̀ náà, ó gbà á sílẹ̀, ó pa àwọn Filistini Olúwa ṣe ìgbàlà ńlá.

13 Mẹ́ta nínú àwọn ọgbọ̀n ìjòyè sọ̀kalẹ̀, wọ́n tọ Dafidi àkókò ìkórè nínú ihò Adullamu, ̀wọ́ àwọn Filistini àfonífojì Refaimu. 14 Dafidi nínú odi, ibùdó àwọn Filistini Bẹtilẹhẹmu nígbà náà. 15 Dafidi ń pòǹgbẹ, ó báyìí , "Ta ni yóò fún mi mu nínú omí kànga ń bẹ Bẹtilẹhẹmu, èyí ó ìhà ẹnu-bodè." 16 Àwọn ọkùnrin alágbára mẹ́ta la ogún àwọn Filistini lọ, wọ́n fa omi láti inú kànga Bẹtilẹhẹmu , èyí ó ìhà ẹnu-bodè, wọ́n tọ Dafidi , òun fẹ́ mu nínú rẹ̀, ṣùgbọ́n ó u sílẹ̀ fún Olúwa. 17 Òun , "a , Olúwa, èmi ó fi ṣe èyí; ṣé èyí ni ̀jẹ̀ àwọn ọkùnrin ó lọ àwọn ̀wọn lọ́wọ́?" Nítorí náà òun fẹ́ un.

Nǹkan wọ̀nyí ni àwọn ọkùnrin alágbára mẹ́tẹ̀̀ta yìí ṣe.

18 Abiṣai, arákùnrin Joabu, ọmọ Seruiah, òun náà ni pàtàkì nínú àwọn mẹ́ta. Òun ni ó gbé ̀kọ̀ rẹ̀ sókè ̀́dúnrún (300) ènìyàn, ó pa wọ́n, ó orúkọ nínú àwọn mẹ́tẹ̀̀ta. 19 Ọlọ́jùlọ ni òun jẹ́ nínú àwọn mẹ́tẹ̀̀ta, ó jẹ́ olórí fún wọn, ṣùgbọ́n òun àwọn mẹ́ta ìṣáájú.

20 Benaiah, ọmọ Jehoiada, ọmọ akọni ọkùnrin kan Kabṣeeli, ẹni ó pọ̀ iṣẹ́ agbára, òun pa àwọn ọmọ Arieli méjì ti Moabu; ó sọ̀kalẹ̀ pẹ̀ó pa kìnnìún kan nínú ihò lákoko òjò-dídì. 21 Ó pa ará Ejibiti kan, ọkùnrin ó dára láti , ará Ejibiti náà ̀kọ̀ kan ọwọ́ rẹ̀, ṣùgbọ́n Benaiah sọ̀kalẹ̀ tọ̀ ́ lọ, pẹ̀̀ọwọ́, ó gba ̀kọ̀ náà lọ́wọ́ ará Ejibiti náà, ó fi ̀kọ̀ rẹ̀ pa á. 22 Nǹkan wọ̀nyí Benaiah ọmọ Jehoiada ṣe, ó orúkọ nínú àwọn ọkùnrin alágbára mẹ́ta náà. 23 Nínú àwọn ọgbọ̀n náà, òun ọlá jùlọ, ṣùgbọ́n òun àwọn mẹ́ta ti ìṣáájú. Dafidi fi í ṣe ìgbìmọ̀ rẹ̀.

24 ̀kan nínú àwọn ọgbọ̀n náà:

Asaheli arákùnrin Joabu Jásí

Elhanani ọmọ Dodo ti Bẹtilẹhẹmu;

25 Ṣamma ará Haroditi,

Elika ará Harodi.

26 Helesi ará Palti,

Ira ọmọ Ikẹsi ará Tekoa;

27 Abieseri ará Anatoti,

Sibekai ará Huṣati;

28 Salmoni ará Ahohi,

Maharai ará Netofa;

29 Heledi ọmọ Baanah, ará Netofa,

Ittai ọmọ Ribai to Gibeah ti àwọn ọmọ Benjamini;

30 Benaiah ará Piratoni,

Hiddai ti àfonífojì Gaaṣi,

31 Abi-Alboni ará Arbati,

Asmafeti Barhumiti;

32 Eliaba ará Ṣaalboni,

àwọn ọmọ Jaṣeni,

Jonatani; 33 ọmọ Ṣamma ará Harari,

Ahiamu ọmọ Ṣarari ará Harari;

34 Elifeleti ọmọ Ahasbai, ọmọ ará Maakati,

Eliamu ọmọ Ahitofeli ará Giloni;

35 Hesro ará Karmeli,

Paarai ará Arba;

36 Igali ọmọ Natani ti Soba,

Bani ará Gadi;

37 Seleki ará Ammoni,

Naharai ará Beeroti, ẹni ń ru ìhámọ́ra Joabu ọmọ Seruiah;

38 Ira ará Itri,

Garebu ará Itri.

39 Uriah ará Hiti.

Gbogbo wọn jẹ́ mẹ́tàdínlógójì.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-