Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuẹli 5

A fi Dafidi jẹ ọba lórí gbogbo Israẹli

1 5.1-3: 1Ki 11.1-3. Gbogbo ̀Israẹli tọ Dafidi Hebroni, wọ́n , "Ẹran-ara rẹ àti ̀jẹ̀ rẹ ni àwa ń í ṣe. 2 Àti nígbà àtijọ́, nígbà Saulu fi jẹ ọba lórí wa, ìwọ ni ẹni ó máa ń Israẹli jáde, ìwọ ni ó máa ń wọn bọ̀ ilé: Olúwa fún , Ìwọ yóò ṣe olùṣọ́ Israẹli àwọn ènìyàn mi, ìwọ yóò jẹ́ olórí fún Israẹli.’ "

3 Gbogbo àgbàgbà Israẹli tọ ọba Hebroni, Dafidi ọba wọn ṣe àdéhùn kan Hebroni, níwájú Olúwa: wọ́n fi òróró yan Dafidi ọba Israẹli.

4 5.4,5: 1Ki 3.4. Dafidi jẹ́ ẹni ọgbọ̀n ọdún nígbà ó jẹ ọba; ó jẹ ọba ogójì ọdún. 5 Ó jẹ ọba Hebroni ọdún méje àti oṣù mẹ́lórí Juda, ó jẹ ọba Jerusalẹmu ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n lórí gbogbo Israẹli àti Juda.

Dafidi fi agbára gba Jerusalẹmu

6 5.6-10: 1Ki 11.4-9. Àti ọba àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ lọ Jerusalẹmu sọ́dọ̀ àwọn ará Jebusi, àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà; àwọn ó ti fún Dafidi , "ṣe ìwọ àwọn afọ́àti àwọn arọ kúrò, ìwọ yóò wọ ìhín ." Wọ́n , "Dafidi yóò síyìn-ín." 7 Ṣùgbọ́n Dafidi fi agbára gba ìlú odi Sioni: èyí náà ni í ṣe ìlú Dafidi.

8 Dafidi sọ lọ́jọ́ náà , "Ẹnikẹ́ni yóò kọlu àwọn ará Jebusi, jẹ́ ó gba ojú àgbàrá, o kọlu àwọn arọ, àti àwọn afọ́ọkàn Dafidi kórìíra." Nítorí náà ni wọ́n ṣe , "Afọ́àti arọ níbẹ̀, yóò wọlé."

9 Dafidi jókòó ilé àwọn ọmọ-ogun ó odi, a ń é ìlú Dafidi. Dafidi mọ ògiri i láti Millo , ó kọ́ ilé nínú rẹ̀. 10 Dafidi ń pọ̀ i, Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun pẹ̀rẹ̀.

11 5.11-12: 1Ki 14.1,2. Hiramu ọba Tire rán àwọn ìránṣẹ́ Dafidi, àti igi kedari, àti àwọn gbẹ́nàgbẹ́, àti àwọn ń gbẹ́ òkúta, wọ́n kọ́ ilé kan fún Dafidi. 12 Dafidi kíyèsi i , Olúwa ti fi ìdí òun múlẹ̀ láti jẹ ọba lórí Israẹli, àti , ó gbé ìjọba rẹ̀ ga nítorí Israẹli àwọn ènìyàn rẹ̀.

13 Dafidi tún àwọn àlè àti aya i láti Jerusalẹmu , lẹ́yìn ìgbà ó ti Hebroni bọ̀, wọ́n ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin fún Dafidi. 14 5.14-16: 1Ki 3.5-8; 14.3-7.Èyí ni orúkọ àwọn a fún un Jerusalẹmu; Ṣammua, Ṣobabu, Natani àti Solomoni. 15 Àti Ibhari, àti Eliṣua, àti Nefegi, àti Jafia. 16 Àti Eliṣama, àti Eliada, àti Elifeleti.

Dafidi ṣẹ́gun àwọn Filistini

17 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn Filistini gbọ́ , wọ́n ti fi Dafidi jẹ ọba lórí Israẹli, gbogbo àwọn Filistini gòkè láti Dafidi; Dafidi gbọ́, ó sọ̀kalẹ̀ lọ ìlú olódi. 18 Àwọn Filistini , wọ́n tẹ ara wọn àfonífojì Refaimu. 19 Dafidi béèrè lọ́dọ̀ Olúwa , "èmi ó gòkè tọ àwọn Filistini ? Ìwọ ó fi wọ́n mi lọ́wọ́ ?"

Olúwa fún Dafidi , "Gòkè lọ, nítorí dájúdájú èmi ó fi àwọn Filistini lọ́wọ́."

20 Dafidi Baali-Perasimu, Dafidi pa wọ́n níbẹ̀, ó , "Olúwa ti ya lu àwọn ̀mi níwájú mi, gẹ́gẹ́ omi ti ń ya." Nítorí náà ni òun ṣe pe orúkọ ibẹ̀ náà ni Baali-Perasimu. 21 Wọ́n fi òrìṣà wọn sílẹ̀ níbẹ̀, Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ wọn.

22 5.22-25: 1Ki 14.13-16. Àwọn Filistini tún gòkè , wọ́n tan ara wọn kalẹ̀ àfonífojì Refaimu. 23 Dafidi béèrè lọ́dọ̀ Olúwa, òun , "ṣe gòkè lọ; ṣùgbọ́n wọ́n lẹ́yìn, o kọlù wọ́n níwájú àwọn igi Baka. 24 Yóò ṣe, nígbà ìwọ gbọ́ ìró ẹsẹ̀ lórí àwọn igi Baka náà, nígbà náà ni ìwọ yóò yára, nítorí nígbà náà ni Olúwa yóò jáde lọ níwájú rẹ láti kọlù ogun àwọn Filistini." 25 Dafidi ṣe bẹ́̀, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún un; ó kọlu àwọn Filistini láti Geba títí Geseri.

Veja também