Publicidade

2 Samuel 7

Ìlérí Ọlọ́run si Dafidi

1 Ó ṣe, nígbà ọba ń gbé ilé rẹ̀, Olúwa fún un ìsinmi yíkákiri kúrò lọ́wọ́ gbogbo àwọn ̀rẹ̀. 2 Ọba fún Natani wòlíì , "ó, èmi ń gbé inú ilẹ̀ a fi kedari kọ́, ṣùgbọ́n àpótí ̀Ọlọ́run ń gbé inú ibi a fi aṣọ ."

3 Natani fún ọba , "Lọ, o ṣe gbogbo èyí ó ọkàn rẹ, nítorí Olúwa pẹ̀rẹ."

Ṣùgbọ́n Ọlọ́run kọ̀ fún Dafidi láti kọ́ tẹmpili

4 Ó ṣe òru náà, ̀rọ̀ Olúwa tọ Natani ,

5 "Lọ, sọ fún ìránṣẹ́ mi, fún Dafidi , Báyìí ni Olúwa , ìwọ ó ha kọ́ ilé fún mi èmi yóò gbé. 6 Nítorí , èmi ì ti gbé inú ilé kan láti ọjọ́ èmi ti àwọn ọmọ Israẹli gòkè ti ilẹ̀ Ejibiti , títí di òní yìí, ṣùgbọ́n èmi ti ń rìn nínú àgọ́, fún ibùgbé mi. 7 ibi gbogbo èmi ti ń rìn pẹ̀gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, ǹjẹ́ èmi ti ̀kan nínú ̀Israẹli, èmi pa àṣẹ fún láti máa bọ́ àwọn ènìyàn mi àní Israẹli, sọ̀rọ̀ , "Èéṣe ̀yin fi kedari kọ́ ilé fún mi." 

8 "Ǹjẹ́, nítorí náà, báyìí ni ìwọ yóò fún ìránṣẹ́ mi àní Dafidi , Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , Èmi ti ìwọ kúrò láti inú agbo àgùntàn láti tẹ̀àwọn àgùntàn, mo fi ́ jẹ olórí àwọn ènìyàn mi, àní Israẹli. 9 Èmi pẹ̀rẹ níbikíbi ìwọ ń lọ, èmi à gbogbo àwọn ̀rẹ kúrò níwájú rẹ, èmi ti sọ orúkọ rẹ di ńlá, gẹ́gẹ́ orúkọ àwọn ènìyàn ńlá ó ayé. 10 Èmi ó yan ibìkan fún àwọn ènìyàn mi, àní Israẹli, èmi ó gbìn wọ́n, wọn ó gbé ibùjókòó tiwọn, wọn yóò sípò padà mọ́; àwọn ọmọ ènìyàn búburú yóò pọ́n wọn lójúmọ́, ìgbà àtijọ́. 11 Àti gẹ́gẹ́ àkókò ìgbà èmi ti fi àṣẹ fún àwọn onídàájọ́ lórí àwọn ènìyàn mi, àní Israẹli, èmi fi ìsinmi fún lọ́wọ́ gbogbo àwọn ̀rẹ.

" Olúwa fún Olúwa yóò kọ ilé kan fún . 12 Nígbà ọjọ́ rẹ , ìwọ ó sùn pẹ̀àwọn baba rẹ, èmi yóò gbé irú-ọmọ rẹ lékè lẹ́yìn rẹ, èyí ó ti inú rẹ jáde , èmi yóò fi ìdí ìjọba rẹ kalẹ̀. 13 Òun ó kọ́ ilé fún orúkọ mi, èmi yóò fi ìdí ìjọba rẹ kalẹ̀ láéláé. 14 Èmi ó máa ṣe baba fún un, òun yóò máa jẹ́ ọmọ mi. òun dẹ́ṣẹ̀, èmi yóò fi ̀ènìyàn án, àti ìnà àwọn ọmọ ènìyàn. 15 Ṣùgbọ́n àánú mi yóò yípadà kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, gẹ́gẹ́ èmi ti un kúrò lọ́dọ̀ Saulu, èmi ti kúrò níwájú rẹ. 16 A ó fi ìdílé rẹ àti ìjọba rẹ múlẹ̀ níwájú rẹ títí láé, a ó fi ìdí ìtẹ́ rẹ múlẹ̀ títí láé.’ "

17 Gẹ́gẹ́ gbogbo ̀rọ̀ wọ̀nyí, àti gẹ́gẹ́ gbogbo ìran yìí, bẹ́̀ ni Natani sọ fún Dafidi.

Àdúrà Dafidi

18 Dafidi ọba wọlé lọ, ó dúró níwájú Olúwa, ó ,

"Olúwa Olódùmarè, ta ni èmi, àti ni ìdílé mi, ìwọ fi mi di ìsinsin yìí? 19 Nǹkan kékeré ni èyí à jásí lójú rẹ, Olúwa Olódùmarè; ìwọ ti sọ nípa ìdílé ìránṣẹ́ rẹ pẹ̀ti àkókò o jìnnà. Èyí ha ṣe ìwà ènìyàn , Olúwa Olódùmarè?

20 "Àti kín ó tún Dafidi ìbá tún máa fún ? Ìwọ, Olúwa Olódùmarè mọ̀ ìránṣẹ́ rẹ. 21 Nítorí ̀rọ̀ rẹ, àti gẹ́gẹ́ ìfẹ́ ọkàn rẹ, ni ìwọ ṣe ṣe gbogbo nǹkan ńlá wọ̀nyí, ìránṣẹ́ rẹ mọ̀.

22 "Ìwọ tóbi, Olúwa Olódùmarè! ẹni ó dàbí rẹ, Ọlọ́run kan lẹ́yìn rẹ̀, gẹ́gẹ́ gbogbo èyí àwa fi etí gbọ́. 23 Orílẹ̀-èdè kan wo ni ó ń bẹ ayé ó dàbí àwọn ènìyàn rẹ, àní Israẹli, àwọn Ọlọ́run lọ padà láti sọ wọ́n di ènìyàn rẹ̀, àti láti sọ wọ́n orúkọ, àti láti ṣe nǹkan ńlá fún un yín, àti nǹkan ìyanu fún ilé rẹ̀, níwájú àwọn ènìyàn rẹ, ìwọ ti padà fún ara rẹ láti Ejibiti , àní àwọn orílẹ̀-èdè àti àwọn òrìṣà wọn. 24 Ìwọ fi ìdí àwọn ènìyàn rẹ, àní Israẹli kalẹ̀ fún ara rẹ láti sọ wọ́n di ènìyàn rẹ títí láé; ìwọ Olúwa di Ọlọ́run fún wọn.

25 "Ǹjẹ́, Olúwa Ọlọ́run, jẹ́ ̀rọ̀ náà ìwọ sọ ti ìránṣẹ́ rẹ, àti ti ìdílé rẹ̀, ó dúró títí láé, ó ṣe ìwọ ti . 26 Jẹ́ orúkọ rẹ ó ga títí láé, , Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni Ọlọ́run lórí Israẹli!jẹ́ a fi ìdílé Dafidi ìránṣẹ́ rẹ múlẹ̀ níwájú rẹ.

27 "Nítorí ìwọ, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli ti sọ létí ìránṣẹ́ rẹ, , Èmí ó kọ́ ilé kan fún .Nítorí náà ni ìránṣẹ́ rẹ ṣe i lọ́kàn rẹ̀ láti gbàdúrà yìí . 28 Ǹjẹ́, Olúwa Olódùmarè, ìwọ ni Ọlọ́run náà, àwọn ̀rọ̀ rẹ jásí òtítọ́, ìwọ jẹ́ ̀jẹ́ nǹkan rere yìí fún ìránṣẹ́ rẹ. 29 Ǹjẹ́, jẹ́ ó ́ láti bùkún ìdílé ìránṣẹ́ rẹ, ó títí láé níwájú rẹ, nítorí ìwọ, Olúwa Olódùmarè, ni ó ti sọ ́: jẹ́ ìbùkún ìdílé ìránṣẹ́ rẹ títí láé, nípasẹ̀ ìbùkún rẹ."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-