Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 20

8 20.8: Ek 23.12; 31.12-17; 34.21; 35.2,3; Le 19.3; De 5.12-15. Rántí ọjọ́ ìsinmi láti á mímọ́. 9 Ọjọ́ mẹ́ni ìwọ yóò fi ṣiṣẹ́, ìwọ ó ṣe gbogbo iṣẹ́ rẹ, 10 ṣùgbọ́n ọjọ́ keje ni ọjọ́ ìsinmi Olúwa Ọlọ́run rẹ: nínú rẹ̀ ìwọ gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ kan: ìwọ, àti ọmọ rẹ ọkùnrin àti ọmọ rẹ obìnrin, ọmọ ̀dọ̀ rẹ ọkùnrin àti ọmọ ̀dọ̀ rẹ obìnrin, àti ẹran ̀sìn rẹ, àti àlejò rẹ, ń bẹ nínú ibodè rẹ.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também