Publicidade

Êxodo 21

1 "Wọ̀nyí ni àwọn òfin ìwọ yóò gbé iwájú wọn.

Òfin nípa Ìwọ̀

2 "ìwọ ọkùnrin Heberu ìwẹ̀, òun yóò sìn ́ fún ọdún mẹ́. Ṣùgbọ́n ọdún keje, òun yóò lọ ni òmìnira láìsan ohunkóhun padà. 3 ó òun nìkan, òun nìkan náà ni yóò padà lọ òmìnira; ṣùgbọ́n ó ìyàwó , ó láti ìyàwó rẹ̀ padà lọ. 4 olówó rẹ̀ fún un aya, aya náà bímọ ọkùnrin àti obìnrin, aya àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò jẹ́ ti olówó rẹ̀, yóò lọ òmìnira òun nìkan.

5 "ẹrú náà gbangba , mo fẹ́ràn olúwa mi, ìyàwó mi àti àwọn ọmọ, èmi fẹ́ ́ gba òmìnira mọ́, 6 nígbà náà ni olúwa rẹ̀ yóò mu iwájú ìdájọ́. Òun yóò un lọ ẹnu-ọ̀tàbí lọ ibi ̀wọ̀n, yóò fi ìlu lu etí rẹ̀, òun yóò máa sin olówó rẹ̀ títí ayé.

7 "ọkùnrin kan ta ọmọbìnrin rẹ̀ ìwẹ̀, ọmọbìnrin yìí gba òmìnira i ti ọmọkùnrin. 8 òun tẹ́ olówó rẹ̀ lọ́rùn, ẹni ó fẹ́ fún ara rẹ̀, yóò jẹ́ wọn ó á padà, òun ̀tọ́ láti á ẹrú fún àjèjì, nítorí òun ni ṣe ojúṣe rẹ̀ pẹ̀ìwẹ̀náà. 9 ó fẹ́ fún ọmọkùnrin rẹ̀, máa ó ìwẹ̀mọ́, ṣùgbọ́n yóò máa ṣe i gẹ́gẹ́ ọmọ rẹ̀ obìnrin. 10 ó fẹ́ obìnrin mìíràn, gbọdọ̀ kùnà ojúṣe rẹ̀ nípa fífún un oúnjẹ àti aṣọ, bẹ́̀ ni gbọdọ̀ kùnà ojúṣe rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọkọ aya. 11 ó kùnà láti ṣe àwọn nǹkan mẹ́ta wọ̀nyí fún un, òun yóò lọ òmìnira láìsan owó kankan padà.

12 "Ẹnikẹ́ni ó lu arákùnrin rẹ̀ pa, pípa ni a ó pa á. 13 Ṣùgbọ́n mọ̀ ́n mọ̀ pa á, ó jẹ́ àmúwá Ọlọ́run ni, òun yóò lọ ibi èmi yóò yàn fún un. 14 Ṣùgbọ́n ó arákùnrin rẹ̀, ó fi ̀tàn pa á. un kúrò iwájú pẹpẹ mi pa á.

15 "Ẹnikẹ́ni ó pa baba tàbí ìyá rẹ̀, pípa ni a ó pa á.

16 "Ẹnikẹ́ni ti ó ènìyàn gbé, ó á tàbí ó fi pamọ́, pípa ni a ó pa á.

17 "Ẹnikẹ́ni ó ṣépè fún baba tàbí ìyá rẹ̀, pípa ni a ó pa á.

18 "àwọn ọkùnrin méjì ń , ti ̀kan sọ òkúta tàbí fi ìkùùkuu lu ẹnìkejì rẹ̀, ó pa á lára, ti irú ìpalára bẹ́̀ mu ó lórí ìdùbúlẹ̀ àìsàn. 19 Ẹni lu ẹnìkejì rẹ̀ ̀bi, níwọ̀n ìgbà ti ẹni a ti dìde, ó è fi ̀ìtìlẹ̀ ọwọ́ rẹ̀ rìn káàkiri. Ẹni náà ni láti san owó ti ó fi tọ́ara rẹ̀ padà fún un, lẹ́yìn ìgbà ara rẹ̀ ti tan pátápátá.

20 "ọkùnrin kan fi ̀lu ẹrúkùnrin tàbí ẹrúbìnrin rẹ̀, ti ẹrú náà lójú ẹsẹ̀, a ó fi ìyà jẹ ́. 21 Ṣùgbọ́n a fi ìyà jẹ ́, ti ẹrú náà , ó dìde lẹ́yìn ọjọ́ kan tàbí méjì, nítorí ẹrú náà jẹ́ dúkìá rẹ̀.

22 "àwọn ènìyàn ti ń pa aboyún lára, aboyún náà bímọ láìpé ọjọ́, ṣùgbọ́n aburú mìíràn mọ́ lẹ́yìn rẹ̀, ẹni ó fa ìpalára yìí yóò san iyekíye ọkọ aboyún náà béèrè fún, ilé ẹjọ́ ṣe gbà láààyè gẹ́gẹ́ owó ìtánràn. 23 Ṣùgbọ́n ìpalára náà yọrí ikú aboyún náà, pípa ni a ó pa ẹni ti ó fa ikú aboyún náà. 24 Ojú fún ojú, eyín fún eyín, ọwọ́ fún ọwọ́, ẹsẹ̀ fún ẹsẹ̀, 25 ìjóná fún ìjóná, ọgbẹ́ fún ọgbẹ́, ìnà fún ìnà.

26 "ọkùnrin kan lu ẹrúkùnrin tàbí ẹrúbìnrin rẹ̀ ojú, ti ojú náà fọ́, ó ni láti jẹ́ ẹrú náà lọ òmìnira fún ìtánràn ojú rẹ̀ ti ó fọ́. 27 ó lu ẹrúkùnrin tàbí ẹrúbìnrin rẹ̀ ti eyín rẹ̀ fi , ó ni láti jẹ́ ó lọ òmìnira ni ìtánràn fún eyín rẹ̀ ó .

28 "akọ màlúù kan ọkùnrin tàbí obìnrin kan pa, a ó sọ akọ màlúù náà òkúta pa, a gbọdọ̀ jẹ ẹran rẹ̀. Ṣùgbọ́n a ẹni ó ni akọ màlúù náà lẹ́bi, ọrùn oní akọ màlúù náà yóò mọ́. 29 Ṣùgbọ́n ó ti di ìgbà gbogbo ti akọ màlúù náà ti máa ń kan ènìyàn, a ti ń kìlọ̀ fún olówó rẹ̀, ti olówó rẹ̀ un so, ó kan ọkùnrin tàbí obìnrin pa, a ó sọ akọ màlúù náà òkúta pa, a ó pa olówó rẹ̀ pẹ̀. 30 àwọn ará ilé ẹni ó béèrè fún owó ìtánràn, yóò san iye owó wọ́n ó san fún owó ìtánràn láti fi ra ̀ara rẹ̀ padà. 31 akọ màlúù kan ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin pa, a ó ṣe gẹ́gẹ́ òfin yìí ti á kalẹ̀. 32 akọ màlúù kan ẹrúkùnrin tàbí ẹrúbìnrin pa, olówó rẹ̀ yóò san ọgbọ̀n ṣékélì fàdákà fún ẹni ni ẹrú, a ó sọ akọ màlúù náà ni òkúta pa.

33 "ọkùnrin kan ṣí kòtò sílẹ̀ láìbò tàbí ó gbẹ́ kòtò sílẹ̀ láìbò, màlúù tàbí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ṣe bẹ́̀ bọ́ sínú kòtò náà. 34 Ẹni ó ni kòtò yóò san owó àdánù yìí fún ẹni ó ni ẹran. Òkú ẹran náà yóò di tirẹ̀.

35 "akọ màlúù ọkùnrin kan pa akọ màlúù ẹlòmíràn lára ó , wọn yóò ta akọ màlúù láààyè, wọn yóò pín owó èyí tiwọn àti ẹran èyí ó dọ́gbadọ́gba. 36 Ṣùgbọ́n ó ti di ìgbà gbogbo akọ màlúù náà máa ń kan òmíràn, olówó rẹ̀ un so, olówó rẹ̀ yóò san ẹran dípò ẹran. Ẹran ó yóò jẹ́ tirẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-