Publicidade

Gênesis 1

Ìbẹ̀rẹ̀ dídá ayé

1 1.1: Jh 1.1. ìbẹ̀rẹ̀ ohun gbogbo Ọlọ́run àwọn ̀run àti ayé. 2 Ayé rúdurùdu, ó ṣófo, òkùnkùn lójú ibú omi, ̀Ọlọ́run ń rábàbà lójú omi.

3 1.3: 2Kọ 4.6. Ọlọ́run , "Jẹ́ ìmọ́lẹ̀ ó ," ìmọ́lẹ̀ . 4 Ọlọ́run i ìmọ́lẹ̀ náà dára, ó ya ìmọ́lẹ̀ náà sọ́tọ̀ kúrò lára òkùnkùn. 5 Ọlọ́run pe ìmọ́lẹ̀ náà "̀sán," àti òkùnkùn "òru." Àṣálẹ́ àti òwúrọ̀ jẹ́ ọjọ́ kìn-ín-ní.

6 1.6-8: 2Pt 3.5. Ọlọ́run , "Jẹ́ òfúrufú ó àárín àwọn omi, láti pààlà àárín àwọn omi." 7 Ọlọ́run òfúrufú láti ya omi ó òkè òfúrufú kúrò lára omi ó orí ilẹ̀. Ó bẹ́̀. 8 Ọlọ́run pe òfúrufú "̀run." Àṣálẹ́ àti òwúrọ̀ jẹ́ ọjọ́ kejì.

9 Ọlọ́run , "Jẹ́ omi abẹ́ ̀run wọ́ papọ̀ ojú kan, ilẹ̀ gbígbẹ farahàn." Ó bẹ́̀. 10 Ọlọ́run pe ilẹ̀ gbígbẹ náà "ilẹ̀," àti àpapọ̀ omi "òkun." Ọlọ́run i ó dára.

11 Ọlọ́run , "Jẹ́ ilẹ̀ ó hu ̀gbìn: ewéko ti yóò máa èso àti igi yóò máa so èso irú tirẹ̀, ó irúgbìn nínú." Ó bẹ́̀. 12 Ilẹ̀ ̀gbìn: ewéko ó ń so èso irú tirẹ̀, àti igi ń so èso, ó irúgbìn nínú irú tirẹ̀. Ọlọ́run ri ó dára. 13 Àṣálẹ́ àti òwúrọ̀ jẹ́ ọjọ́ kẹta.

14 Ọlọ́run , "Jẹ́ ìmọ́lẹ̀ ó ojú ̀run, láti pààlà àárín ̀sán àti òru, wọn ó máa fún àmì láti mọ àwọn àsìkò, àti àwọn ọjọ́ àti àwọn ọdún. 15 wọn ó jẹ́ ìmọ́lẹ̀ ojú ̀run láti tan ìmọ́lẹ̀ orí ilẹ̀." Ó bẹ́̀. 16 Ọlọ́run ìmọ́lẹ̀ ńlá ńlá méjì, ìmọ́lẹ̀ ó tóbi láti ṣe àkóso ̀sán àti ìmọ́lẹ̀ ó kéré láti ṣe àkóso òru. Ó àwọn ìràwọ̀ pẹ̀. 17 Ọlọ́run ṣe wọ́n lọ́jọ̀ ojú ̀run láti máa tan ìmọ́lẹ̀ si orí ilẹ̀, 18 láti ṣàkóso ̀sán àti òru àti láti pààlà àárín ìmọ́lẹ̀ àti òkùnkùn. Ọlọ́run i ó dára. 19 Àṣálẹ́ àti òwúrọ̀ jẹ́ ọjọ́ kẹrin.

20 Ọlọ́run , "Jẹ́ omi ó kún fún àwọn ohun alààyè, àwọn ẹyẹ ó máa òfúrufú." 21 Nítorí náà Ọlọ́run àwọn ̀alààyè ńlá ńlá inú òkun, àwọn ohun ẹlẹ́mìí àti àwọn ohun ń rìn onírúurú tiwọn, àti àwọn ẹyẹ abìyẹ́ onírúurú tiwọn. Ọlọ́run i ó dára. 22 Ọlọ́run súre fún wọn, ó , "máa i, máa pọ̀ i, kún inú omi òkun, àwọn ẹyẹ náà máa pọ̀ i orí ilẹ̀." 23 Àṣálẹ́ àti òwúrọ̀ jẹ́ ọjọ́ karùn-ún.

24 Ọlọ́run , "ilẹ̀ ó ohun alààyè jáde onírúurú wọn: ẹran ̀sìn, àwọn ohun afàyàfà àti àwọn ẹran inú igbó, ̀kọ̀̀kan irú tirẹ̀." Ó bẹ́̀. 25 Ọlọ́run ẹranko inú igbó àti ẹran ̀sìn gbogbo irú tirẹ̀ àti gbogbo ohun alààyè ń rìn ilẹ̀ irú tirẹ̀. Ọlọ́run i ó dára.

26 1.26,27: Gẹ 5.1; Mt 19.4; Mk 10.6; Kl 3.10; Jk 3.9. Lẹ́yìn náà ni Ọlọ́run , "jẹ́ a ènìyàn àwòrán ara wa, gẹ́gẹ́ àwa ti , wọn ó jẹ ọba lórí ẹja òkun, ẹyẹ ojú ̀run, ẹran ̀sìn, gbogbo ilẹ̀ àti lórí ohun gbogbo ń rìn lórí ilẹ̀."

27 1.27,28: Gẹ 5.1,2. 1.27: Mt 19.4; Mk 10.6. Nítorí náà, Ọlọ́run ènìyàn àwòrán ara rẹ̀,

àwòrán Ọlọ́run ni ó a,

akọ àti abo ni ó wọn.

28 Ọlọ́run súre fún wọn, Ọlọ́run fún wọn , "máa i, máa pọ̀ i, gbilẹ̀, ṣe ìkápá ayé. ṣe àkóso àwọn ẹja inú òkun, ẹyẹ ojú ̀run àti gbogbo ̀alààyè ó ń rìn orí ilẹ̀."

29 Nígbà náà ni Ọlọ́run , "Mo fi gbogbo ohun ̀gbìn ń so èso fún un yín oúnjẹ àti àwọn igi eléso pẹ̀. Gbogbo rẹ̀ yóò jẹ́ oúnjẹ fún un yín. 30 Àti fún àwọn ẹranko inú igbó àti ẹyẹ ojú ̀run àti àwọn ohun afàyàfà, gbogbo ohun èémí ìyè nínú ni mo fi ewéko fún oúnjẹ." Ó bẹ́̀.

31 Ọlọ́run àwọn ohun gbogbo ó , ó dára gidigidi. Àṣálẹ́ àti òwúrọ̀ jẹ́ ọjọ́ kẹfà.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_15-35-42-