Pular para o conteúdo
Publicidade

Gênesis 12

Ìpè Abramu

1 12.1: Ap 7.3; Hb 11.8. Olúwa fún Abramu, "Jáde kúrò orílẹ̀-èdè rẹ àti kúrò lọ́dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ, lọ ilẹ̀ kan èmi yóò fihàn ́.

2 12.2: Gẹ 15.5; 17.4,5; 18.18; 22.17; 28.14; 32.12; 35.11; 46.3. "Èmi yóò sọ ́ di orílẹ̀-èdè ńlá,

èmi yóò bùkún fún ;

èmi yóò sọ orúkọ rẹ di ńlá,

ìbùkún ni ìwọ yóò jásí.

3 12.3: Gẹ 18.18; 22.17,18; 26.4; 28.14; Ga 3.8. Èmi yóò bùkún fún àwọn ó súre fún ,

ẹni ó fi ́ ni Èmi yóò fi ;

nínú rẹ ni a ó bùkún

gbogbo ìdílé ayé."

4 Bẹ́̀ ni Abramu lọ Olúwa ti sọ fún un. Lọti náà a lọ. Abramu jẹ́ ẹni àrùndínlọ́gọ́rin ọdún nígbà ó jáde kúrò Harani. 5 Abramu Sarai aya rẹ̀, àti Lọti ọmọ arákùnrin rẹ̀: gbogbo ohun ìní wọ́n ti kójọ àti àwọn ènìyàn wọ́n Harani. Wọ́n jáde lọ ilẹ̀ Kenaani. Wọ́n gúnlẹ̀ síbẹ̀.

6 Abramu rìn la ilẹ̀ náà títí ibi igi ńlá kan à ń ni More Ṣekemu. Àwọn ará Kenaani ilẹ̀ náà. 7 12.7: Gẹ 13.15; 15.18; 17.8; 24.7; 26.3; 28.4,13; 35.12; 48.4; Ap 7.5; Ga 3.16.Olúwa farahan Abramu, ó fún un , "Irú-ọmọ rẹ ni Èmi yóò fi ilẹ̀ yìí fún." Abramu tẹ́ pẹpẹ kan síbẹ̀ fún Olúwa ó fi ara hàn án.

8 Ó kúrò níbẹ̀ lọ agbègbè àwọn òkè kan ìhà ìlà-oòrùn Beteli, ó pàgọ́ rẹ̀ síbẹ̀. Beteli ìwọ̀-oòrùn, Ai ìlà-oòrùn. Ó tẹ́ pẹpẹ kan níbẹ̀ fún Olúwa, ó pe orúkọ Olúwa.

9 Nígbà náà ni Abramu tẹ̀síwájú ìhà gúúsù.

Abramu Ejibiti

10 12.10-20: Gẹ 20.1-18; 26.7-11. Ìyàn kan ilẹ̀ náà, Abramu sọ̀kalẹ̀ lọ Ejibiti láti ṣe àtìpó níbẹ̀ fún ìgbà díẹ̀, nítorí ìyàn náà gidigidi. 11 ó ti ku díẹ̀ ó wọ Ejibiti, ó fún Sarai, aya rẹ̀ , "Mo mọ̀ arẹwà obìnrin ni ìwọ, 12 nígbà àwọn ará Ejibiti , wọn yóò , Aya rẹ̀ nìyí.Wọn yóò si pa , ṣùgbọ́n wọn yóò . 13 Nítorí náà, sọ , arábìnrin mi ni ìwọ, wọn yóò ṣe dáradára, a ó ̀mi nítorí tìrẹ."

14 Nígbà Abramu Ejibiti, àwọn ará Ejibiti ri i aya rẹ̀ rẹwà gidigidi. 15 Nígbà àwọn ìjòyè Farao i, wọ́n ròyìn rẹ̀ níwájú Farao, wọ́n un lọ ààfin. 16 Ó kẹ́ Abramu dáradára nítorí Sarai, Abramu àgùntàn àti màlúù, akọ àti abo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin, pẹ̀ìbákasẹ.

17 Olúwa rán àjàkálẹ̀-ààrùn búburú Farao àti ilé rẹ̀, nítorí Sarai aya Abramu. 18 Nítorí náà Farao ránṣẹ́ pe Abramu, ó fun , "Èwo ni ìwọ ṣe mi yìí? ìwọ sọ fún mi aya rẹ í ṣe? 19 Èéṣe o fi , Arábìnrin mi ni,èmi fi fẹ́ gẹ́gẹ́ aya? Nítorí náà nísinsin yìí, aya rẹ náà nìyí, un o máa lọ." 20 Nígbà náà ni Farao pàṣẹ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ nípa Abramu, wọ́n e jáde ti òun ti aya rẹ̀ àti ohun gbogbo ó .

Veja também