Pular para o conteúdo
Publicidade

Gênesis 16

Hagari àti Iṣmaeli

1 Sarai, aya Abramu bímọ fún un, ṣùgbọ́n ó ọmọ ̀dọ̀ obìnrin ará Ejibiti kan ń jẹ́ Hagari. 2 Nítorí náà, Sarai fún Abramu , "Kíyèsi i Olúwa ti mi inú, èmi bímọ, wọlé tọ ọmọ ̀dọ̀ mi lọ, bóyá èmi yóò le ti ipasẹ̀ rẹ̀ ọmọ."

Abramu gba ohun Sarai sọ. 3 Lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá Abramu ti ń gbé ni Kenaani ni Sarai ọmọbìnrin, ọmọ ̀dọ̀ rẹ Hagari, í ṣe ará Ejibiti fún Abramu ọkọ rẹ̀ láti fi ṣe aya. 4 Abramu Hagari lòpọ̀, ó lóyún.

Nígbà ó ti mọ̀ òun lóyún, ó bẹ̀rẹ̀ kẹ́gàn ̀rẹ̀. 5 Nígbà náà ni Sarai fún Abramu , "Ìwọ ni ó jẹ́ ̀gbin yìí máa jẹ , mo fa ọmọ ̀dọ̀ mi lọ́wọ́, nígbà ó i òun lóyún, mo di ẹni ̀gàn ojú rẹ̀. Olúwa ó ṣe ìdájọ́ láàrín tèmi tìrẹ."

6 Abramu dáhùn , "Ìwọ ni ọmọ ̀dọ̀ rẹ, ṣe ohunkóhun ó tọ́ ojú rẹ i." Nígbà náà ni Sarai fi ìyà jẹ Hagari, ó sálọ.

7 Angẹli Olúwa Hagari ̀gbẹ́ ìsun omi ijù, ìsun omi ó ̀gbẹ́ ̀ó lọ Ṣuri. 8 Ó , "Hagari, ìránṣẹ́ Sarai, níbo ni o ti ń bọ̀, níbo ni ìwọ ń lọ?"

Ó dáhùn , "Mo ń sálọ kúrò lọ́dọ̀ ̀mi Sarai ni."

9 Angẹli Olúwa fún un , "Padà lọ ̀dọ̀ ̀rẹ o tẹríba fún un." 10 Angẹli Olúwa náà fi kún fún un , "Èmi yóò sọ ́ di orílẹ̀-èdè ńlá, ìran rẹ yóò lóǹkà."

11 Angẹli Olúwa náà fún un ,

"Ìwọ ti lóyún,

ìwọ yóò ọmọkùnrin kan.

Ìwọ yóò pe orúkọ rẹ̀ Iṣmaeli,

nítorí Olúwa ti ìpọ́njú rẹ.

12 Òun yóò jẹ́ oníjàgídíjàgan ènìyàn

ọwọ́ rẹ̀ yóò lára ènìyàn gbogbo,

ọwọ́ ènìyàn gbogbo yóò lára rẹ̀,

yóò máa gbé ìkanra

pẹ̀àwọn arákùnrin rẹ̀."

13 Ó pe orúkọ Olúwa o sọ̀rọ̀ , "Ìwọ ni Ọlọ́run ó mi," nítorí ó , "Mo ti ri ẹni ó mi báyìí." 14 Nítorí náà ni a ṣe ń pe kànga náà Beeri-Lahai-Roi; kànga ẹni alààyè ó mi. Ó agbede-méjì Kadeṣi àti Beredi.

15 16.15: Ga 4.22. Hagari ọmọkùnrin kan fún Abramu, Abramu pe orúkọ rẹ̀ Iṣmaeli. 16 Abramu jẹ́ ẹni ọdún mẹ́rìndínláàádọ́rùn-ún nígbà Hagari Iṣmaeli fún un.

Veja também