Publicidade

Gênesis 17

Májẹ̀Ilà abẹ́ kíkọ

1 ìgbà Abramu di ẹni ̀kàndínlọ́gọ́rùn-ún ọdún, Olúwa farahàn án, ó , "Èmi ni Ọlọ́run alágbára, máa rìn níwájú mi, o jẹ́ aláìlábùkù. 2 Èmi yóò fi ìdí májẹ̀mi múlẹ̀ pẹ̀rẹ. Èmi yóò sọ ́ di púpọ̀ gidigidi."

3 Abramu dojúbolẹ̀, Ọlọ́run fún un . 4 "ti èmi, májẹ̀mi pẹ̀rẹ nìyí. Ìwọ yóò di baba orílẹ̀-èdè púpọ̀. 5 A yóò pe orúkọ rẹ̀ Abramu mọ́, ṣe Abrahamu, nítorí, mo ti sọ ́ di baba orílẹ̀-èdè púpọ̀. 6 Èmi yóò si lọ́pọ̀lọ́pọ̀, ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè ni èmi yóò ti ara rẹ jáde , àwọn ọba pẹ̀yóò ti inú rẹ jáde. 7 Èmi yóò gbé májẹ̀mi kalẹ̀ láàrín tèmi tìrẹ, májẹ̀ayérayé àti láàrín irú-ọmọ rẹ ìran-ìran wọn, láti máa ṣe Ọlọ́run rẹ àti ti irú-ọmọ rẹ lẹ́yìn rẹ. 8 Gbogbo ilẹ̀ Kenaani níbi ìwọ ti ṣe àjèjì ni èmi yóò fi fún àti fún irú-ọmọ rẹ lẹ́yìn rẹ láéláé. Èmi yóò jẹ́ Ọlọ́run wọn."

9 Nígbà náà ni Ọlọ́run fún Abrahamu , "Ìwọ máa pa májẹ̀mi mọ́, ìwọ àti irú-ọmọ rẹ lẹ́yìn rẹ àti àwọn ìran ó ń bọ̀. 10 Èyí ni májẹ̀mi pẹ̀rẹ àti ìran rẹ lẹ́yìn rẹ, májẹ̀̀yin yóò máa pamọ́. Gbogbo ọkùnrin yín ni a gbọdọ̀ kọ ilà. 11 ̀yin yóò kọ ara yín ilà, èyí ni yóò jẹ́ àmì májẹ̀láàrín tèmi tiyín. 12 gbogbo ìran ń bọ̀ lẹ́yìn, gbogbo ọkùnrin ni a gbọdọ̀ kọ ni ilà ọjọ́ kẹjọ a wọn, àti àwọn a ilé rẹ, tàbí a fi owó lọ́wọ́ àwọn àjèjì, àwọn í ṣe ọmọ rẹ̀. Èyí yóò jẹ́ májẹ̀láéláé yóò láàrín Èmi àti irú-ọmọ rẹ. 13 Ìbá à ṣe ẹni a nínú ilé rẹ, tàbí ẹni o fi owó , a gbọdọ̀ kọ wọ́n ilà; májẹ̀lára yín yóò jẹ́ májẹ̀ayérayé. 14 Gbogbo ọmọkùnrin kọ ilà, a kọ ilà abẹ́, ni a ó kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀, nítorí ó da májẹ̀mi."

15 Ọlọ́run fún Abrahamu , "ti Sarai, aya rẹ̀, ìwọ yóò é Sarai mọ́, ṣe Sara. 16 Èmi yóò bùkún fún un, èmi yóò fun ọmọkùnrin kan nípasẹ̀ rẹ̀. Èmi yóò bùkún un, yóò di ìyá àwọn orílẹ̀-èdè, àwọn ọba àwọn orílẹ̀-èdè yóò ti ara rẹ̀ jáde ."

17 Abrahamu dojúbolẹ̀, ó rẹ́rìn-ín, ó fún ara rẹ̀ , "A ó ha ọmọ fún ẹni ọgọ́rùn-ún ọdún? Sara í ṣe ẹni àádọ́rùn-ún ọdún yóò ha bímọ ?" 18 Abrahamu fún Ọlọ́run , "à jẹ́ Iṣmaeli ó láààyè lábẹ́ ìbùkún rẹ."

19 Nígbà náà ni Ọlọ́run , "Mo gbọ́, ṣùgbọ́n Sara aya rẹ̀ yóò ọmọkùnrin kan fún , ìwọ yóò pe orúkọ rẹ̀ Isaaki, èmi yóò fi ìdí májẹ̀mi múlẹ̀ pẹ̀rẹ̀ májẹ̀ayérayé àti àwọn irú-ọmọ rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀. 20 Ṣùgbọ́n ti Iṣmaeli, mo gbọ́ ohun ìwọ , èmi yóò bùkún fún un nítòótọ́, èmi ó un i, yóò pọ̀ i, òun yóò jẹ́ baba fún àwọn ọmọ ọba méjìlá, bẹ́̀ ni èmi yóò sọ ́ di orílẹ̀-èdè ńlá. 21 Ṣùgbọ́n èmi yóò fi ìdí májẹ̀mi múlẹ̀ pẹ̀Isaaki, ẹni Sara yóò fún ni ìwòyí àmọ́dún." 22 Nígbà ó ti Abrahamu sọ̀rọ̀ tán, Ọlọ́run gòkè lọ kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀.

23 ọjọ́ náà gan an ni Abrahamu Iṣmaeli ọmọ rẹ̀ àti àwọn ẹrú a ilé rẹ̀ àti àwọn ó fi owó , ó kọ wọ́n ilà. Bẹ́̀ ni ó kọ gbogbo ọkùnrin ń bẹ ilé rẹ̀ ilà gẹ́gẹ́ àṣẹ Ọlọ́run. 24 Abrahamu jẹ́ ẹni ̀kàndínlọ́gọ́rùn-ún ọdún nígbà a kọ ́ ilà. 25 Iṣmaeli ọmọ rẹ̀ jẹ́ ẹni ọdún mẹ́tàlá. 26 ọjọ́ náà gan an ni a kọ Abrahamu ilà pẹ̀Iṣmaeli ọmọ rẹ̀ ọkùnrin. 27 Àti gbogbo ọkùnrin ó ilé Abrahamu, ìbá à ṣe èyí a ilé rẹ̀ tàbí èyí a fi owó lọ́wọ́ àlejò ni a kọ ilà pẹ̀rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-