Pular para o conteúdo
Publicidade

Gênesis 18

10 18.10: Ro 9.9. Nígbà náà ni Olúwa fún un , "Èmi yóò tún padà tọ̀ ́ nítòótọ́ ìwòyí àmọ́dún; Sara aya rẹ yóò ọmọkùnrin kan."

Sara ń dẹtí gbọ́ láti ẹnu-ọ̀àgọ́ ó lẹ́yìn ọkùnrin náà. 11 Abrahamu àti Sara ti di arúgbó, Sara ti kọjá àsìkò ìbímọ. 12 18.12: 1Pt 3.6.Nítorí náà, Sara rẹ́rìn-ín nínú ara rẹ̀ ó ti ń ó lọ́kàn rẹ̀ , "Lẹ́yìn ìgbà mo ti di arúgbó tán olúwa mi pẹ̀ti gbó jọ̀kújọ̀, èmi yóò ha tún bímọ?"

Veja também