Publicidade

Gênesis 2

1 2.1-3: Ek 20.11. Báyìí ni Ọlọ́run parí dídá àwọn ̀run àti ayé, àti ohun gbogbo ó nínú rẹ̀.

2 2.2,3: Ek 20.11. 2.2: Hb 4.4,10. ọjọ́ keje Ọlọ́run parí iṣẹ́ rẹ̀ ó ti ń ṣe; ó sinmi ọjọ́ keje kúrò nínú iṣẹ́ rẹ̀ gbogbo ó ti ń ṣe. 3 Ọlọ́run súre fún ọjọ́ keje, ó á mímọ́, nítorí ọjọ́ náà ni ó sinmi kúrò nínú iṣẹ́ dídá ayé ó ti ń ṣe.

Adamu àti Efa

4 Èyí ni ìtàn Ọlọ́run ṣe àwọn ̀run àti ayé nígbà ó wọn. Nígbà Olúwa Ọlọ́run ayé àti àwọn ̀run.

5 igi igbó kan orí ilẹ̀, bẹ́̀ ni ewéko igbó kan ó ì jáde ilẹ̀, nítorí Olúwa Ọlọ́run ì rọ̀sórí ilẹ̀, ènìyàn láti ro ilẹ̀. 6 Ṣùgbọ́n ìsun omi ń jáde láti ilẹ̀, ó ń bu omi rin gbogbo ilẹ̀. 7 2.7: 1Kọ 15.45-47.Olúwa Ọlọ́run fi erùpẹ̀ ilẹ̀ mọ ènìyàn, ó si èémí ìyè ihò imú rẹ̀, ènìyàn di alààyè ọkàn.

8 Olúwa Ọlọ́run gbin ọgbà kan Edeni ìhà ìlà-oòrùn, níbẹ̀ ni ó fi ọkùnrin náà ó ti . 9 2.9: If 2.7; 22.2,14,19.Olúwa Ọlọ́run onírúurú igi jáde láti inú ilẹ̀, àwọn igi ó dùn ún lójú, ó dára fún oúnjẹ. àárín ọgbà náà ni igi ìyè àti igi ń ènìyàn mọ rere àti búburú .

10 Odò kan ń ti Edeni sàn láti bu omi rin ọgbà náà, láti ibẹ̀ ni odò náà gbé ya ipa mẹ́rin. 11 Orúkọ èkínní ni Pisoni, òun ni ó sàn gbogbo ilẹ̀ Hafila , níbi wúrà gbé . 12 (Wúrà ilẹ̀ náà dára, òjìá2.12 tí ó túmọ̀ sí, bedeliumu àti òkúta óníkìsì oníyebíye níbẹ̀ pẹ̀). 13 Orúkọ odò kejì ni Gihoni, òun ni ó sàn gbogbo ilẹ̀ Kuṣi . 14 Orúkọ odò kẹta ni Tigirisi, òun ni ó sàn apá ìlà-oòrùn ilẹ̀ Asiria. Odò kẹrin ni Eufurate.

15 Olúwa Ọlọ́run ọkùnrin náà sínú ọgbà Edeni láti máa ṣe iṣẹ́ níbẹ̀, ó máa ṣe ìtọ́rẹ̀. 16 Olúwa Ọlọ́run pàṣẹ fún ọkùnrin náà , "Ìwọ jẹ lára èyíkéyìí èso àwọn igi inú ọgbà; 17 ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ jẹ nínú èso igi ìmọ̀ rere àti èso igi ìmọ̀ búburú, nítorí ọjọ́ ìwọ jẹ ́ ni ìwọ yóò kùú."

18 Olúwa Ọlọ́run , "dára ọkùnrin òun nìkan. Èmi yóò ṣe olùrànlọ́wọ́ ó i rẹ̀ fún un."

19 Lẹ́yìn Olúwa Ọlọ́run ti àwọn ẹranko inú igbó àti gbogbo ẹyẹ ojú ̀run láti inú erùpẹ̀ ilẹ̀. Ó wọn tọ ọkùnrin náà láti wo orúkọ yóò sọ wọ́n; orúkọ ó sọ gbogbo ̀alààyè náà ni wọ́n ń jẹ́. 20 Gbogbo ohun ̀sìn, ẹyẹ ojú ̀run àti gbogbo ẹranko igbó ni ọkùnrin náà sọ orúkọ.

Ṣùgbọ́n fún Adamu ni a olùrànlọ́wọ́ ó i rẹ̀. 21 Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run ọkùnrin náà sùn fọnfọn; nígbà ó ń sùn, Ọlọ́run yọ egungun ìhà rẹ̀ kan, ó fi ẹran-ara ó padà. 22 Olúwa Ọlọ́run obìnrin láti inú egungun ó yọ ìhà ọkùnrin náà, Ó mu obìnrin náà tọ̀ ́ .

23 Ọkùnrin náà ,

"Èyí ni egungun láti inú egungun mi

àti ẹran-ara nínú ẹran-ara mi;

obìnrinni a ó máa é,

nítorí a un jáde láti ara ọkùnrin."

24 2.24: Mt 19.5; Mk 10.7; 1Kọ 6.16; Ef 5.31. Nítorí ìdí èyí, ọkùnrin yóò fi baba àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀, yóò dàpọ̀ mọ́ aya rẹ̀, wọn yóò di ara kan.

25 Ọkùnrin náà àti aya rẹ̀ ìhòhò, ojú wọ́n.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-