Publicidade

Gênesis 22

Ọlọ́run dán Abrahamu

1 Nígbà ó ṣe, Ọlọ́run dán Abrahamu , ó é, ó , "Abrahamu."

Abrahamu dáhùn , "Èmi nìyí."

2 Ọlọ́run , "ọmọ rẹ, àní Isaaki ọmọ rẹ kan ṣoṣo , ìwọ fẹ́ràn, lọ ilẹ̀ Moria, o fi ẹbọ sísun níbẹ̀ lórí ̀kan nínú àwọn òkè èmi yóò sọ fún ."

3 Abrahamu dìde kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ó di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ gàárì, ó méjì nínú àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ àti Isaaki ọmọ rẹ̀, ó ṣẹ́ igi fún ẹbọ sísun, ó gbéra lọ ibi Ọlọ́run ti sọ fún un. 4 Nígbà ó di ọjọ́ kẹta, Abrahamu gbé ojú sókè, ó ibi ó ń lọ òkèrè, 5 Abrahamu fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ , "̀yin, dúró níhìn-ín pẹ̀kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, èmi àti ọmọ yìí yóò lọ ohunkóhun láti sin Ọlọ́run, a ó tún padà a yín."

6 Abrahamu gbé igi ẹbọ sísun náà ru Isaaki, òun fúnra rẹ̀ iná àti ̀bẹ. àwọn méjèèjì ti ń lọ, 7 Isaaki sọ fún Abrahamu baba rẹ̀ , "Baba mi."

Abrahamu dalóhùn , "Èmi nìyí ọmọ mi."

Isaaki tún , "ó iná àti igi nìyí, ṣùgbọ́n níbo ni ̀dọ́-àgùntàn fún ẹbọ sísun náà ?"

8 Abrahamu dáhùn , "Ọmọ mi, Ọlọ́run fúnra rẹ̀ ni yóò pèsè ̀dọ́-àgùntàn fún ẹbọ sísun náà." Bẹ́̀ ni àwọn méjèèjì jùmọ̀ ń lọ.

9 Nígbà wọn ibi Ọlọ́run sọ fún Abrahamu, ó mọ pẹpẹ kan, ó to igi e lórí, ó di Isaaki ọmọ rẹ̀, ó da dùbúlẹ̀ lórí pẹpẹ náà. 10 Abrahamu nawọ́ ̀bẹ, láti dúńbú ọmọ rẹ̀. 11 Ṣùgbọ́n angẹli Olúwa i láti ̀run "Abrahamu! Abrahamu!"

Abrahamu dáhùn , "Èmi nìyí."

12 Angẹli Olúwa , "ṣe fọwọ́ kan ọmọ náà, ìwọ gbọdọ̀ ṣe é ni ohun kan. Nísinsin yìí ni mo mọ̀ o bẹ̀Ọlọ́run, nítorí ìwọ fi ọmọ rẹ, àní, ọmọ rẹ kan ṣoṣo ."

13 Abrahamu gbójú sókè, ó àgbò kan ó fi ìwo pàǹtírí, ó lọ un, ó fi ẹbọ sísun dípò ọmọ rẹ̀. 14 Abrahamu pe orúkọ ibẹ̀ ni, Jehofah Jire. Bẹ́̀ ni a ń títí di òní olónìí , "orí òkè Olúwa, ni a ó ti pèsè."

15 Angẹli Olúwa tún pe Abrahamu láti ̀run lẹ́̀kejì. 16 Ó , Olúwa , "Mo fi ara mi búra, níwọ̀n ìwọ ti ṣe èyí, ìwọ fi ọmọ rẹ, àní, ọmọ rẹ kan ṣoṣo , 17 nítòótọ́, bíbùkún èmi ó bùkún fún , àti bíbísí èmi ó i i ìràwọ̀ ojú ̀run àti iyanrìn etí Òkun. Irú-ọmọ rẹ yóò gba ẹnu ibodè àwọn ̀wọn, 18 àti nípasẹ̀ irú-ọmọ rẹ ni a ó ti bùkún fún gbogbo orílẹ̀-èdè ayé nítorí ìwọ gbọ́rọ̀ mi lẹ́nu."

19 Nígbà náà ni Abrahamu padà tọ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ lọ. Gbogbo wọn padà lọ Beerṣeba. Abrahamu jókòó Beerṣeba.

Àwọn ọmọ Nahori

20 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí ni a fún Abrahamu , "Milka aya Nahori àwọn ọmọkùnrin fún un.

21 Usi àkọ́rẹ̀, Busi arákùnrin rẹ̀,

Kemueli (baba Aramu).

22 Kesedi, Haso, Pildasi, Jidlafi, àti Betueli."

23 Betueli ni baba Rebeka.

Milka àwọn ọmọ mẹ́jọ wọ̀nyí fún Nahori arákùnrin Abrahamu.

24 Àlè rẹ̀ ń jẹ́ Reuma náà àwọn ọmọkùnrin wọ̀nyí fun un:

Teba, Gahamu, Tahasi àti Maaka.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-